Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 30

̀rọ̀ ìbànújẹ́ Jobu

1 "Ṣùgbọ́n nísinsin yìí,

àwọn mo gbà àbúrò ń fi ṣe ẹlẹ́

baba ẹni èmi kẹ́gàn

láti pẹ̀àwọn ajá nínú agbo ẹran mi.

2 ni ìwúlò agbára ọwọ́ wọn mi,

níwọ̀n ìgbà agbára wọn ti fi wọ́n sílẹ̀?

3 Wọ́n nítorí àìní àti ìyàn

wọ́n ń rìn káàkiri ilẹ̀ gbígbẹ

ibi ìkọ̀sílẹ̀ òru.

4 Àwọn ẹni ń ewé iyọ̀ ̀igbó;

gbogbo igikígi ni oúnjẹ jíjẹ wọn.

5 A wọn kúrò láàrín ènìyàn,

àwọn ènìyàn pariwo wọn lórí ẹní pariwo olè lórí.

6 A wọn gbe inú pàlàpálá òkúta àfonífojì,

nínú ihò ilẹ̀ àti ti òkúta.

7 Wọ́n ń dún àárín igbó

wọ́n ara wọn jọ pọ̀ abẹ́ ̀gún neteli.

8 Àwọn ọmọ ẹni òye ,

àní àwọn ọmọ lásán, a wọn jáde kúrò orí ilẹ̀.

9 "Ǹjẹ́ nísinsin yìí, àwọn ọmọ wọn ń fi ṣe ẹlẹ́nínú orin;

àní èmi di ẹni ìṣọ̀rọ̀ láàrín wọn.

10 Wọ́n kórìíra mi; wọ́n kúrò jìnnà mi,

wọn bìkítà láti tutọ́ mi lójú.

11 Nítorí Ọlọ́run ti okùn ìyè mi, ó pọ́n mi lójú;

àwọn pẹ̀dẹ ìdẹ̀kùn níwájú mi.

12 Àwọn ènìyàn lásán dìde apá ̀tún mi;

wọ́n ẹsẹ̀ mi kúrò,

wọ́n la ipa ̀ìparun sílẹ̀ .

13 Wọ́n da ipa ̀mi ;

wọ́n sọ ìparun mi di púpọ̀,

àwọn olùrànlọ́wọ́.

14 Wọ́n ya mi i omi ó ya gbuuru;

ariwo ńlá ni wọ́n rọ́ .

15 ̀ńlá ;

wọ́n lépa ọkàn mi ̀fúùfù,

àlàáfíà mi kọjá lọ àwọ̀ sánmọ̀.

16 "Àti nísinsin yìí, ayé mi n yòrò lọ díẹ̀díẹ̀;

ọjọ́ ìpọ́njú mi mímú.

17 Òru gún mi nínú egungun mi,

èyí ó jẹ sinmi.

18 Nípa agbára ńlá rẹ̀ Ọlọ́run aṣọ ìbora fún mi,

ó lẹ̀ mọ́ mi ara yíká aṣọ ìlekè mi.

19 Ọlọ́run ti mi lọ sínú ẹrẹ̀,

èmi dàbí eruku àti eérú.

20 "Èmi ́ ìwọ Ọlọ́run, ṣùgbọ́n ìwọ mi lóhùn;

èmi dìde dúró ìwọ lásán.

21 Ìwọ padà di ẹni ìkà mi;

ọwọ́ agbára rẹ ni ìwọ fi ̀.

22 Ìwọ gbé mi sókè inú ̀fúùfù, ìwọ mi lọ,

bẹ́̀ ni ìwọ sọ di asán pátápátá.

23 Èmi à mọ̀ ìwọ yóò mi lọ sínú ikú,

ilé ìpéjọ a yàn fún gbogbo alààyè.

24 "ó ti ó , ẹnìkan yóò ha nawọ́ rẹ̀ nígbà ìṣubú rẹ̀,

tàbí yóò nínú ìparun rẹ̀.

25 Èmi ha sọkún fún ẹni ó nínú ìṣòro?

Ọkàn mi ha bàjẹ́ fún tálákà ?

26 Nígbà mo fojú ṣọ́fún àlàáfíà, ibi ;

nígbà mo dúró de ìmọ́lẹ̀, òkùnkùn .

27 Ikùn n ru sinmi,

ọjọ́ ìpọ́njú ti mi.

28 Èmí ń rìn kiri nínú ̀fọ̀, ṣùgbọ́n í ṣe nínú oòrùn;

èmi dìde dúró àwùjọ mo kígbe fún ìrànlọ́wọ́.

29 Èmi ti di arákùnrin ìkookò,

èmi di ẹgbẹ́ àwọn ògòǹgò.

30 Àwọ̀ mi di dúdú ara mi;

egungun mi jórun fún ooru.

31 Ohun èlò orin mi pẹ̀di ti ̀fọ̀,

àti ìpè orin mi di ohùn àwọn ń sọkún.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também