Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 21

Jobu Sofari lóhùn

1 Jobu dáhùn, ó ,

2 "tẹ́sílẹ̀ dáradára àwọn ̀rọ̀ mi,

èyí ó jásí ìtùnú fún mi.

3 jọ̀wọ́ mi ki èmi sọ̀rọ̀;

lẹ́yìn ìgbà ìwọ le máa fi mi ṣẹ̀sín ń ṣo.

4 "Àròyé mi ha ṣe ènìyàn ?

Èétise ọkàn mi yóò fi ṣe àìbalẹ̀?

5 fín, ẹnu ó yín,

fi ọwọ́ ẹnu yín.

6 Àní nígbà mo rántí, ̀,

ìwárìrì mi lára.

7 Nítorí ènìyàn búburú fi ayé,

wọ́n gbó, àní wọ́n di alágbára ipa?

8 Irú-ọmọ wọn fi ìdí kalẹ̀ ojú

wọn pẹ̀wọn, àti ọmọ ọmọ wọn ojú wọn.

9 Ilé wọn láìní ewu àti ̀,

bẹ́̀ ni ̀ìbínú Ọlọ́run lára wọn.

10 Akọ màlúù wọn a máa gùn, í tàsé;

abo màlúù wọn a máa , í í ṣẹ́yun.

11 Wọn a máa rán àwọn ọmọ wọn

wẹ́wẹ́ jáde agbo ẹran, àwọn ọmọ wọn a máa jo kiri.

12 Wọ́n ohun ̀orin, ìlù àti haapu;

wọ́n ń yọ̀ ohùn fèrè.

13 Wọ́n n lo ọjọ́ wọn nínú ọrọ̀;

wọn lọ ipò òkú àlàáfíà.

14 Nítorí náà ni wọ́n ṣe fún Ọlọ́run , Lọ kúrò lọ́dọ̀ wa!

Nítorí wọn fẹ́ ìmọ̀ ipa ̀rẹ.

15 ni Olódùmarè àwa ó fi máa sìn in?

Èrè ni a ó jẹ àwa ba gbàdúrà i?

16 Kíyèsi i, àlàáfíà wọn nípa ọwọ́ wọn;

ìmọ̀ ènìyàn búburú jìnnà mi réré.

17 "Ìgbà mélòó mélòó a ń pa fìtílà ènìyàn búburú ?

Ìgbà mélòó mélòó ìparun wọn wọn,

Ọlọ́run í máa pín ìbìnújẹ́ nínú ìbínú rẹ̀?

18 Wọ́n dàbí àgékù koríko níwájú afẹ́fẹ́,

àti ìyàngbò, ̀fúùfù ńlá fẹ́ lọ.

19 ̀yin , Ọlọ́run to ìyà ̀ṣẹ̀ rẹ̀ jọ fún àwọn ọmọ rẹ̀.’

Jẹ́ ó san án fún un, yóò mọ̀ ́n.

20 Ojú rẹ̀ yóò ìparun ara rẹ̀,

yóò máa mu nínú ríru ìbínú Olódùmarè.

21 Nítorí àlàáfíà ni ó nínú ilé rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀,

nígbà a iye oṣù rẹ̀ kúrò agbede-méjì?

22 "Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni le kọ Ọlọ́run ìmọ̀?

Òun í à ń ṣe ìdájọ́ ẹni ibi gíga.

23 Ẹnìkan a nínú pípé agbára rẹ̀,

ó nínú ìrora àti ìdákẹ́ pátápátá.

24 Ọpọ́n rẹ̀ kún fún omi ọmú,

egungun rẹ̀ tutù fún ̀.

25 Ẹlòmíràn a nínú kíkorò ọkàn rẹ̀,

fi inú dídùn jẹun.

26 Wọ́n o dùbúlẹ̀ bákan náà nínú erùpẹ̀,

kòkòrò yóò ṣùbò wọ́n.

27 "Kíyèsi i, èmi mọ̀ èrò inú yín àti

àrékérekè ọkàn yín láti ṣe ìlòdì mi.

28 Nítorí ̀yin , Níbo ilé ọmọ-aládé,

àti níbo àgọ́ àwọn ènìyàn búburú gbé ?

29 ̀yin béèrè lọ́wọ́ àwọn ń kọjá lọ ̀?

̀yin mọ̀ àmì wọn,

30 ènìyàn búburú a fi pamọ́ fún ọjọ́ ìparun.

A ó wọn jáde ọjọ́ ríru ìbínú.

31 Ta ni yóò tako ipa ̀rẹ̀ lójúkojú,

ta ni yóò san án padà fún un èyí ó ti ṣe?

32 Síbẹ̀ a ó sin ín ̀ipò òkú,

a ó máa ṣọ́ ibojì òkú.

33 Ògúlùtu àfonífojì yóò dùn mọ́ ọn.

Gbogbo ènìyàn yóò máa tọ̀ ́ lẹ́yìn,

ènìyàn àìníye ti lọ síwájú rẹ̀.

34 "Èéha ti ṣe ̀yin fi ń nínú lásán,

ò ṣe ìdáhùn yín, àrékérekè wa níbẹ̀!"

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também