Pular para o conteúdo
Publicidade

Jobu 20

Ìdáhùn Sofari

1 Ìgbà náà Sofari, ará Naama dáhùn, ó ,

2 "Nítorí náà ìrò inú mi mi lóhùn,

àti nítorí èyí náà mo yára si gidigidi.

3 Mo ti gbọ́ ̀san ̀gàn mi,

̀òye mi mi lóhùn.

4 "Ìwọ mọ̀ èyí ìgbà àtijọ́,

láti ìgbà a sọ ènìyàn lọ́jọ̀ sílé ayé,

5 , orin ayọ̀ ènìyàn búburú, ìgbà kúkúrú ni,

àti , ìṣẹ́kan ayọ̀ àgàbàgebè?

6 ọláńlá rẹ̀ tilẹ̀ gòkè ̀run,

ti orí rẹ̀ kan àwọsánmọ̀;

7 ṣùgbọ́n yóò ṣègbé láéláé ìgbẹ́ ara rẹ̀;

àwọn ó ti i yóò , Òun ha ?

8 Yóò lọ àlá, a yóò i,

àní a ó e lọ bi ìran òru.

9 Ojú ó ti i yóò i mọ́,

bẹ́̀ ni ibùjókòó rẹ̀ yóò ri i mọ́.

10 Àwọn ọmọ rẹ̀ yóò máa àti ojúrere lọ́dọ̀ tálákà,

ọwọ́ rẹ̀ yóò ọrọ̀ wọn padà.

11 Egungun rẹ̀ kún fún agbára ìgbà èwe rẹ̀,

yóò a dùbúlẹ̀ nínú erùpẹ̀.

12 "ìwà búburú tilẹ̀ dún ẹnu rẹ̀,

ó tilẹ̀ pa á mọ́ nísàlẹ̀ ahọ́n rẹ̀,

13 ó tilẹ̀ a , si kọ̀ ́ sílẹ̀,

ó pa á mọ́ síbẹ̀ ẹnu rẹ̀,

14 ṣùgbọ́n oúnjẹ rẹ̀ nínú ikùn rẹ̀ ti yípadà,

ó jásí òróró paramọ́lẹ̀ nínú rẹ̀;

15 Ó ti gbé ọrọ̀ , yóò tún i jáde;

Ọlọ́run yóò pọ̀ ́ yọ jáde láti inú rẹ̀ .

16 Ó ti oró paramọ́lẹ̀ ;

ahọ́n ejò olóró yóò pa á.

17 yóò odò wọ̀n-ọn-nì,

ìṣàn omi, odò ń ṣàn fún oyin àti ti òrí-àmọ́.

18 Ohun ó ṣiṣẹ́ fún ni yóò un padà, yóò gbé e ;

gẹ́gẹ́ ọrọ̀ ó , yóò ìgbádùn nínú rẹ̀.

19 Nítorí ó fi owó rẹ̀ ni tálákà lára, ó ti pẹ̀yìndà si wọ́n;

nítorí ti ó fi agbára gbé ilé òun kọ́.

20 "Nítorí òun mọ̀ ìwà pẹ̀lẹ́ nínú ara rẹ̀,

yóò gbà nínú èyí ọkàn rẹ̀ fẹ́ sílẹ̀.

21 Ohun kan fún jíjẹ́ rẹ̀;

nítorí náà ̀rọ̀ rẹ̀ yóò dúró pẹ́.

22 Nínú ànító rẹ̀, ìdààmú yóò a;

àwọn ènìyàn búburú yóò dáwọ́jọ e lórí.

23 Yóò ṣe, nígbà ó fẹ́ jẹun,

Ọlọ́run yóò ríru ìbínú rẹ̀ í lórí, nígbà ń jẹun lọ́wọ́,

yóò rọ òjò ìbínú rẹ̀ e lórí.

24 Bi o tilẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ohun ìjà ìrìn;

ọrun akọ irin yóò ta a po yọ.

25 O á yọ, ó jáde kúrò lára;

idà dídán ń jáde láti inú òróòro .

̀ńlá ń bẹ ara rẹ̀;

26 òkùnkùn biribiri a ti pamọ́ fún ìṣúra rẹ̀.

Iná ti a fẹ́ yóò o run

yóò jẹ èyí ó nínú àgọ́ rẹ̀ run.

27 ̀run yóò fi ̀ṣẹ̀ rẹ hàn,

ayé yóò dìde dúró i.

28 Ìbísí ilé rẹ̀ yóò kọjá lọ,

àti ohun ìní rẹ̀ yóò sàn dànù lọ ni ọjọ́ ìbínú Ọlọ́run.

29 Èyí ni ìpín ènìyàn búburú láti ̀dọ̀ Ọlọ́run ,

àti ogún a yàn sílẹ̀ fún un láti ̀dọ̀ Ọlọ́run."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também