Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 26

Àgọ́ náà

1 26.1-14: Ek 36.8-19. "Ṣe àgọ́ náà pẹ̀aṣọ títa mẹ́wàá, aṣọ ̀gbọ̀ olókùn wíwẹ́ àti aṣọ aláró, ti elése àlùkò, àti ti òdòdó, pẹ̀àwọn kérúbù ni ó ṣe iṣẹ́ ọlọ́wọn. 2 Gbogbo aṣọ títa náà ni ó jẹ́ ìwọ̀n kan náà: ìgbọ̀nwọ́ méjìdínlọ́gbọ̀n (28) gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rin ni fífẹ̀. 3 Aṣọ títa márùn-ún ni a so papọ̀ mọ́ ara wọn, àti aṣọ títa márùn-ún ni a so papọ̀ mọ́ ara wọn. 4 Ìwọ yóò ṣì ṣe ajábó aṣọ aláró aṣọ títa kan láti ìṣẹ́rẹ̀ níbi ìsopọ̀, àti bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni ìwọ yóò ṣe ni etí ìkangun aṣọ títa kejì, ni ibi ìsopọ̀ kejì. 5 Àádọ́ta ajábó ó pa lára aṣọ títa kan, àti àádọ́ta ajábó ni ó pa etí aṣọ títa ó ìsolù kejì, ajábó náà ̀kánkán ara wọn. 6 Ó ṣe àádọ́ta ìkọ́ wúrà, ó ìkọ́ wọ̀n-ọn-nì láti fi aṣọ títa kan kọ́ èkejì, bẹ́̀ ó di odidi àgọ́ kan.

7 "Ìwọ ó ṣe aṣọ títa irun ewúrẹ́ láti fi ṣe ìbò sórí àgọ́ náàaṣọ títa mọ́kànlá ni ìwọ ó ṣe é. 8 Gbogbo aṣọ títa mọ́kọ̀̀kànlá náà jẹ́ ìwọ̀n kan náà, ọgbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rin fífẹ̀. 9 Ìwọ ó so aṣọ títa márùn-ún pọ̀ mọ́ ara wọn se ̀kan, ó tún so mẹ́tókù mọ́ ara wọn se ̀kan. Ìwọ ó ṣẹ́ aṣọ títa kẹfà po méjì níwájú àgọ́ náà. 10 Ìwọ ó pa àádọ́ta ajábó ìṣẹ́ìkangun aṣọ títa apá kan, wọ́n tún pa ajábó mìíràn ìṣẹ́ìkangun aṣọ títa apá kejì. 11 Nígbà náà ṣe àádọ́ta ìkọ́ idẹ o wọn sínú ̀jábó láti fi so àgọ́ náà pọ̀ ó jẹ́ ̀kan. 12 Àti ìyókù ó nínú aṣọ títa àgọ́ náà, ìdajì aṣọ títa ó , yóò rọ̀ sórí ̀yìn àgọ́ náà. 13 Aṣọ títa àgọ́ náà yóò jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan gígùn ìhà méjèèjì, èyí ó yóò rọ̀ sórí ìhà àgọ́ náà láti fi ó. 14 Ìwọ ó ṣe ìbòrí awọ àgbò a pupa fún àgọ́ náà, ó ṣe ìbòrí awọ seali sórí rẹ̀.

15 "Ìwọ ó ṣe pákó igi kasia ó dúró òró fún àgọ́ náà. 16 26.16-29: Ek 36.20-34.pákó kọ̀̀kan jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́wàá gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ fífẹ̀. 17 Pẹ̀ìtẹ̀bọ̀ méjì ni ó kọjú ara wọn. Ṣe gbogbo àwọn pákó àgọ́ náà èyí. 18 Ìwọ ó ṣe ogún pákó ìhà gúúsù àgọ́ náà, 19 ìwọ ó ṣe ogójì ìhà ìtẹ̀bọ̀ fàdákà ó lọ ìsàlẹ̀ wọn. Méjì fún pákó kọ̀̀kan, ̀kan ìsàlẹ̀ ìtẹ̀bọ̀ kọ̀̀kan. 20 Àti ìhà kejì, ni ìhà àríwá àgọ́ náà, ṣe ogún pákó síbẹ̀ 21 àti ogójì ihò ìtẹ̀bọ̀ fàdákà méjì abẹ́ pákó kọ̀̀kan. 22 ìwọ ó ṣe pákó mẹ́ìkangun, ìkangun ìhà ìwọ̀-oòrùn àgọ́ náà, 23 o ṣe pákó méjì fún igun ìhà ̀yìn. 24 igun méjèèjì yìí, wọ́n gbọdọ̀ jẹ́ méjì láti ìdí orí rẹ̀, a ó so wọ́n pọ̀ òrùka kan: méjèèjì yóò bákan náà. 25 Wọn ó jẹ́ pákó mẹ́jọ, àti ihò ìtẹ̀bọ̀ fàdákà mẹ́rìnlélógún, méjì ìsàlẹ̀ ̀kọ̀̀kan.

26 "Ìwọ ó ṣe ̀ìdábùú igi kasia; márùn-ún fún pákó ìhà kan àgọ́ náà, 27 márùn-ún fún àwọn ìhà kejì, àti márùn-ún fún pákó ni ìhà ìwọ̀-oòrùn ìhà ̀yìn àgọ́ náà. 28 ̀ìdábùú àárín ni agbede-méjì gbọdọ̀ tàn láti ìkangun ìkangun pákó náà. 29 Ìwọ́ ó bo àwọn pákó náà pẹ̀wúrà, o ṣe òrùka wúrà ó di ̀ìdábùú mu. o tún bo ̀ìdábùú náà pẹ̀wúrà.

30 "Gbé àgọ́ náà gẹ́gẹ́ àpẹẹrẹ a fihàn ́ lórí òkè.

31 26.31-37: Ek 36.35-38. "Ìwọ ó ṣe aṣọ ìgélé aláró, àti elése àlùkò, àti òdòdó, àti ̀gbọ̀ olókùn wẹ́wẹ́ í ṣe ọlọ́, òun ti àwọn kérúbù ni á ṣe é. 32 Ìwọ yóò fi rọ̀ sára òpó ó di igi kasia mẹ́rin a fi wúrà , ó dúró lórí ihò ìtẹ̀bọ̀ mẹ́rin mẹ́rin. 33 Ṣo aṣọ títa náà ìsàlẹ̀ àwọn ìkọ́, o gbé àpótí ̀̀gbẹ́ aṣọ títa náà. Aṣọ títa náà yóò pínyà Ibi Mímọ́ kúrò Ibi Mímọ́ Jùlọ. 34 Fi ìtẹ́ àánú bo àpótí ̀náà ni Ibi Mímọ́ Jùlọ. 35 Gbé tábìlì náà ìta aṣọ títa náà ìhà gúúsù àgọ́ náà, o gbé ̀fìtílà òdìkejì rẹ̀ ìhà àríwá.

36 "Fún ti ẹnu-ọ̀àgọ́ náà, ìwọ yóò ṣe aṣọ títa aláró, elése àlùkò, ti òdòdó àti ti ̀gbọ̀ olókùn wíwẹ́ a fi iṣẹ́ abẹ́rẹ́ ṣe. 37 Ìwọ ó ṣe ìkọ́ wúrà fún aṣọ títa yìí, àti òpó igi ṣittimu márùn-ún a fi wúrà . o ihò ìtẹ̀bọ̀ idẹ márùn-ún fún wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também