Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 30

Pẹpẹ tùràrí

1 30.1-5: Ek 37.25-29. "Ìwọ yóò ṣe pẹpẹ igi kasia kan; máa tùràrí lórí rẹ̀. 2 igun mẹ́rẹ̀̀rin rẹ̀ ṣe déédé, ó jẹ́ ìdajì mita gígùn, ìdajì mita fífẹ̀ àti ìgbọ̀nwọ́ méjì ni gíga rẹ̀—ìwo rẹ̀ pẹ̀rẹ̀. 3 Ìwọ yóò bo òkè rẹ̀, gbogbo ìhà rẹ̀ àti ìwo rẹ̀ pẹ̀u kìkì wúrà, ìwọ yóò ṣe wúrà gbà á yíká. 4 Ìwọ yóò ṣe òrùka wúrà méjì fún pẹpẹ náà níṣàlẹ̀ ìgbátí méjèèjì òdìkejì ìhà rẹ̀—láti gbá àwọn òpó rẹ̀ , láti máa fi gbé e. 5 Ìwọ yóò ṣe òpó igi kasia, ìwọ yóò bọ́ wọ́n pẹ̀wúrà. 6 Ìwọ yóò gbé pẹpẹ náà iwájú aṣọ ìkélé, èyí ó níwájú àpótí ̀níwájú ìtẹ́ àánú èyí ó lórí àpótí ̀níbi ti èmi yóò ti máa pàdé.

7 "Aaroni yóò máa tùràrí dídùn lórí pẹpẹ náà àràárọ̀, nígbà ó tún àwọn fìtílà náà ṣe. 8 Aaroni yóò tún tùràrí nígbà ó tan fìtílà àṣálẹ́, bẹ́̀ tùràrí yóò máa títí láé níwájú Olúwa fún àwọn ìran ń bọ̀. 9 ̀yin gbọdọ̀ àjèjì tùràrí sórí pẹpẹ yìí tàbí ẹbọ sísun kankan tàbí ọrẹ oúnjẹ, bẹ́̀ ni ̀yin gbọdọ̀ da ẹbọ ohun mímu sórí i rẹ̀. 10 Aaroni yóò máa ṣe ètùtù sórí àwọn ìwo rẹ̀ lẹ́̀kan lọ́dún. Òun yóò máa ṣe ètùtù ọdọọdún yìí pẹ̀̀jẹ̀ ẹbọ ètùtù fún ìran ń bọ̀. Mímọ́ jùlọ ni Olúwa."

Ètùtù owó

11 30.11-16: Ek 38.25,26. Nígbà náà ni Olúwa fún Mose , 12 "Nígbà ìwọ ka iye àwọn ọmọ Israẹli láti mọ iye wọn, ẹnìkọ̀̀kan wọn gbọdọ̀ ìràpadà ọkàn rẹ̀ fún Olúwa ìgbà o ka iye wọn. Nígbà náà ni àjàkálẹ̀-ààrùn yóò súnmọ́ wọn, nígbà o ń ka iye wọn. 13 Olúkúlùkù ẹrù ó kọjá lọ sọ́dọ̀ àwọn a ti yóò san ìdajì ṣékélì, gẹ́gẹ́ ṣékélì ibi mímọ́, èyí ó wọn ogún gera. Ìdajì ṣékélì yìí ọrẹ fún Olúwa. 14 Gbogbo àwọn ó kọjá sínú àwọn a láti ẹni ogún ọdún tàbí bẹ́̀ lọ, ni yóò fi ọrẹ fún Olúwa. 15 Àwọn olówó yóò san ju ìdajì ṣékélì lọ, àwọn tálákà gbọdọ̀ dín ìdajì ṣékélì nígbà ̀yin ọrẹ fún Olúwa láti ṣe ètùtù fún ọkàn yín. 16 Ìwọ yóò gba owó ètùtù náà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Israẹli, ìwọ yóò fi lélẹ̀ fún ìsìn àgọ́ àjọ. Yóò jẹ́ ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli níwájú Olúwa, láti ṣe ètùtù fún ọkàn yín."

Agbada fún wíwẹ̀

17 Nígbà náà ni Olúwa fún Mose , 18 30.18: Ek 38.8."Ìwọ yóò ṣe agbada idẹ kan, àti ẹsẹ̀ rẹ̀ idẹ, fún wíwẹ̀. Ìwọ yóò gbé e àárín àgọ́ àjọ àti pẹpẹ náà, ìwọ yóò pọn omi sínú rẹ̀. 19 Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò máa wẹ ọwọ́ àti ẹsẹ̀ wọn pẹ̀omi ó nínú rẹ̀. 20 Nígbàkígbà wọ́n wọ inú àgọ́ àjọ, wọ́n yóò wẹ̀ pẹ̀omi nítorí wọ́n ba à . Bákan náà, nígbà wọ́n súnmọ́ ibi pẹpẹ láti ṣe ìsìn, láti ẹbọ ti a fi iná sun fún Olúwa, 21 wọn yóò wẹ ọwọ́ wọn àti ẹsẹ̀ wọn, nítorí wọn máa ba à . Èyí ni yóò jẹ́ ìlànà títí láé fún Aaroni àti irú àwọn ọmọ rẹ̀ fún ìrandíran wọn."

Òróró ìyàsímímọ́

22 30.22-33: Ek 37.29. Olúwa sọ fún Mose , 23 "Ìwọ yóò ààyò tùràrí olóòórùn ̀dọ̀ rẹ; ̀́dẹ́gbẹ̀ta ṣékélì (kilogiramu mẹ́) òjìá ṣíṣàn, ìdajì ó yẹ àádọ́ta nígba (250) ṣékélì kinamoni dídùn, àti kénì dídùn àádọ́ta nígba (250) ṣékélì, 24 kasia ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) ṣékélì gbogbo rẹ̀ ìlànà ṣékélì ibi mímọ́ àti hínì òróró olifi kan (lita mẹ́rin). 25 Ṣe ìwọ̀nyí òróró mímọ́ ìkunra, a gẹ́gẹ́ olùṣe òórùn dídùn í ṣe. Yóò jẹ òróró mímọ́ ìtasórí. 26 Ìwọ yóò ó láti ya àgọ́ mímọ́ àti àpótí ̀náà, 27 tábìlì àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, ̀fìtílà àti ohun èlò rẹ̀, àti pẹpẹ tùràrí, 28 pẹpẹ ẹbọ sísun àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, àti agbada pẹ̀ẹsẹ̀ rẹ̀. 29 Ìwọ yóò sọ wọ́n di mímọ́, nítorí wọn jẹ́ mímọ́ jùlọ, àti ohunkóhun ó fi ọwọ́ kàn wọn yóò di mímọ́.

30 "Ìwọ yóò ta òróró orí Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀, ìwọ yóò sọ wọ́n di mímọ́, nítorí wọn sìn àlùfáà. 31 Ìwọ yóò sọ fún àwọn ọmọ Israẹli , Èyí ni yóò ṣe òróró mímọ́ ìtasórí mi fún ìrandíran ń bọ̀. 32 ṣe á ara ènìyàn o ṣe ṣe òróró kankan ni irú rẹ̀. Mímọ́ ni, ̀yin gbọdọ̀ á mímọ́. 33 Ẹnikẹ́ni ó po irú rẹ̀, tàbí ẹnikẹ́ni ó fi sára àlejò yàtọ̀ àlùfáà, a ó e kúrò nínú àwọn ènìyàn rẹ̀.’ "

Tùràrí

34 Olúwa sọ fún Mose , "tùràrí olóòórùn dídùn sọ́dọ̀ rẹ, onika, àti galibanumu àti kìkì tùràrí dáradára, òsùwọ̀n kan fún gbogbo rẹ, 35 ṣe tùràrí olóòórùn dídùn a , iṣẹ́ àwọn olóòórùn, ó iyọ̀, ó dára, ó jẹ́ mímọ́. 36 Ìwọ yóò lọ díẹ̀ nínú rẹ̀ kúnná, ìwọ yóò gbé e síwájú ̀àgọ́ àjọ, níbi èmi yóò ti pàdé yín. Yóò jẹ́ mímọ́ jùlọ fún yín. 37 ṣe ṣe tùràrí kankan irú èyí fúnra yín; á mímọ́ Olúwa. 38 Ẹnikẹ́ni ó ṣe irú rẹ̀ láti máa gbádùn òórùn rẹ̀, òun ni a ó kúrò nínú àwọn ènìyàn rẹ̀."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também