Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 35

Àwọn ìlànà ọjọ́ ìsinmi

1 Mose pe gbogbo ìjọ Israẹli ó fún wọn , "Wọ̀nyí ni àwọn ohun ti Olúwa ti pàṣẹ fún un yín láti ṣe. 2 35.2,3: Ek 23.12; 31.12-17; 34.21; De 5.12-15.Fún ọjọ́ mẹ́ni fi ṣiṣẹ́, ṣùgbọ́n ọjọ́ keje yóò jẹ́ ọjọ́ mímọ́ fún yín, ọjọ́ ìsinmi ni Olúwa. Ẹnikẹ́ni ó ṣe iṣẹ́ kankan ni ọjọ́ náà a ó pa. 3 ṣe dáná kankan ibùgbé yín ọjọ́ ìsinmi."

Ohun èlò fun Àgọ́

4 35.4-9: Ek 25.1-9. Mose sọ fún gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli , "Èyí ni ohun Olúwa pàṣẹ. 5 Láti inú ohun ni ni ti ọrẹ fún Olúwa. Ẹnikẹ́ni ó fẹ́ ni ó ọrẹ fún Olúwa ti:

"wúrà, fàdákà àti idẹ;

6 aṣọ aláró, elése àlùkò, òdòdó àti ̀gbọ̀ dáradára;

àti irun ewúrẹ́;

7 awọ àgbò a kùn pupa àti awọ màlúù;

odò igi kasia;

8 òróró olifi fún títan iná;

olóòórùn fún òróró ìtasórí, àti fún tùràrí dídùn;

9 òkúta óníkìsì àti òkúta a ̀efodu àti ìgbàyà.

10 "Gbogbo ẹni ó ọgbọ́n láàrín yín, ó wa, ó ṣe gbogbo ohun Olúwa ti pàṣẹ:

11 "àgọ́ náà pẹ̀àgọ́ rẹ àti ìbòrí rẹ̀, kọ́kọ́rọ́ rẹ̀, pákó rẹ̀, ̀rẹ̀, ̀wọ́n rẹ̀ àti ihò ìtẹ̀bọ̀ rẹ̀;

12 Àpótí náà pẹ̀̀rẹ̀, ìbò àánú àti aṣọ títa náà ó síji ó.

13 Tábìlì náà pẹ̀òpó rẹ̀ àti gbogbo ohun èlò rẹ̀ àti àkàrà ìfihàn náà.

14 ̀fìtílà ó fún títanná pẹ̀ohun èlò rẹ̀, fìtílà àti òróró fún títanná.

15 Pẹpẹ tùràrí náà pẹ̀ẹsẹ̀ rẹ̀, òróró ìtasórí àti tùràrí dídùn;

aṣọ títa fún ̀ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀àgọ́ náà.

16 Pẹpẹ ẹbọ sísun pẹ̀ojú ààrò idẹ rẹ̀, òpó rẹ̀ àti gbogbo ohun èlò rẹ̀;

agbada idẹ pẹ̀ẹsẹ̀ rẹ̀.

17 Aṣọ títa ti àgbàlá pẹ̀, ̀wọ́n àti ihò ìtẹ̀bọ̀ rẹ̀ àti aṣọ títa fún ẹnu-ọ̀àgbàlá náà.

18 Èèkàn àgọ́ náà fún àgọ́ náà àti fún àgbàlá àti okùn wọn.

19 Aṣọ híhun láti ṣiṣẹ́ ibi mímọ́ aṣọ mímọ́ fún Aaroni àlùfáà àti aṣọ fún àwọn ọmọ rẹ̀ nígbà wọ́n sìn àlùfáà."

20 Gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli kúrò níwájú Mose, 21 olúkúlùkù ẹni ó fẹ́ àti ẹni ọkàn rẹ̀ gbé sókè , wọ́n ọrẹ fún Olúwa, fún iṣẹ́ àgọ́ àjọ, fún gbogbo ìsìn rẹ̀ àti fún aṣọ mímọ́ náà. 22 Gbogbo àwọn ó fẹ́, ọkùnrin àti obìnrin, wọ́n wọ́n onírúurú ìlẹ̀kẹ̀ wúrà: òrùka etí, òrùka àti ̀ṣọ́. Gbogbo wọn wúrà gẹ́gẹ́ ọrẹ fún Olúwa. 23 Olúkúlùkù ẹni ó ni aṣọ aláró elése àlùkò, òdòdó àti ̀gbọ̀ dáradára, tàbí irun ewúrẹ́, awọ àgbò a pupa tàbí awọ màlúù odò, ó wọn . 24 Àwọn ó ọrẹ fàdákà tàbí idẹ , ọrẹ fún Olúwa, àti olúkúlùkù ẹni ó igi ṣittimu fún ipa kankan nínú iṣẹ́ un . 25 Gbogbo àwọn obìnrin ó ọgbọ́n ríran owú pẹ̀ọwọ́ rẹ̀, ó èyí ti ó ti ran ti aláró, ti elése àlùkò, ti òdòdó tàbí ti ̀gbọ̀ dáradára. 26 Gbogbo àwọn obìnrin ó fẹ́, ó ọgbọ́n ń ran òwú irun ewúrẹ́. 27 Àwọn olórí òkúta óníkìsì láti ó lórí ̀efodu àti ìgbàyà. 28 Wọ́n tún olóòórùn àti òróró olifi fún títanná àti fún òróró ìtasórí àti fún tùràrí dídùn. 29 Gbogbo àwọn ènìyàn Israẹli ọkùnrin àti obìnrin ẹni ó fẹ́ ọrẹ àtinúwá fún Olúwa fún gbogbo iṣẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún wọn láti ṣe nípasẹ̀ Mose.

Besaleli àti Oholiabu

30 35.30–36.1: Ek 31.1-6. Nígbà náà ni Mose fún àwọn ọmọ Israẹli , "ó, Olúwa ti yan Besaleli ọmọ Uri, ọmọ Huri, ti ̀Juda, 31 Ó ti fi ̀Ọlọ́run kún un, pẹ̀ọgbọ́n, òye, ìmọ̀ àti gbogbo onírúurú iṣẹ́ ọnà. 32 Láti máa ṣe aláràbarà iṣẹ́ ti wúrà, fàdákà àti idẹ, 33 láti gbẹ́ òkúta àti láti ó, láti fún igi àti láti ṣiṣẹ́ ni gbogbo onírúurú iṣẹ́ ọnà. 34 Ó fún òun àti Oholiabu ọmọ Ahisamaki ti ̀Dani, ni agbára láti kọ́ àwọn tókù. 35 Ó fi ọgbọ́n kún wọn láti ṣe gbogbo onírúurú iṣẹ́, ti oníṣọ̀, ti ayàwòrán, ti aránsọ, ti aláṣọ aláró, ti elése àlùkò, ti òdòdó àti ̀gbọ̀ dáradára àti ti ahunṣọ, gbogbo èyí ̀oníṣẹ́-ọnà àti ayàwòrán ń ṣe.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também