Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 36

1 Besaleli, Oholiabu àti olúkúlùkù ọlọ́gbọ́n ẹni Olúwa fún ọgbọ́n àti òye láti mọ a ti í ṣe gbogbo iṣẹ́ ibi mímọ́ ni wọn ṣe iṣẹ́ náà gẹ́gẹ́ Olúwa ti pa á láṣẹ."

2 Mose pe Besaleli àti Oholiabu àti gbogbo ọlọ́gbọ́n ènìyàn ẹni Olúwa ti fún ni agbára àti gbogbo ẹni ó fẹ́ láti iṣẹ́ náà. 3 Wọ́n gba gbogbo ọrẹ àwọn ọmọ Israẹli ti lọ́wọ́ Mose fún kíkọ́ ibi mímọ́ náà. Àwọn ènìyàn ń ọrẹ àtinúwá àràárọ̀. 4 Bẹ́̀ ni gbogbo àwọn ọlọ́gbọ́n oníṣẹ́-ọnà wọn ń ṣe gbogbo iṣẹ́ ibi mímọ́ náà fi iṣẹ́ wọn sílẹ̀. 5 Mose , "Àwọn ènìyàn púpọ̀ fún ṣíṣe iṣẹ́ náà ju bi Olúwa ti pa á láṣẹ láti ṣe lọ."

6 Mose pàṣẹ, wọ́n rán iṣẹ́ yìí gbogbo ibùdó: "ọkùnrin tàbí obìnrin ṣe ṣe ohun kankan ọrẹ fún ibi mímọ́ náà mọ́." Bẹ́̀ ni a àwọn ènìyàn lẹ́kun láti un i, 7 nítorí ohun wọ́n ti ti ju ohun wọn fẹ́ fi ṣe gbogbo iṣẹ́ náà lọ.

Àgọ́ náà

8 36.8-19: Ek 26.1-14. Gbogbo àwọn ọlọ́gbọ́n ọkùnrin láàrín àwọn òṣìṣẹ́ ni wọ́n ṣe iṣẹ́ náà pẹ̀aṣọ títa mẹ́wàá ti ̀gbọ̀ olókùn dáradára, aṣọ aláró, ti elése àlùkò àti ti òdòdó, pẹ̀àwọn kérúbù ṣe iṣẹ́ wọn nípa ọgbọ́n iṣẹ́ ọnà. 9 Gbogbo aṣọ títa náà ni ó jẹ́ ìwọ̀n kan náà: ìgbọ̀nwọ́ méjìdínlọ́gbọ̀n (28) gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rin ni fífẹ̀. 10 Aṣọ títa márùn-ún ni a so papọ̀ mọ́ ara wọn, àti aṣọ títa márùn-ún ni a so papọ̀ mọ́ ara wọn. 11 Ìwọ yóò ṣì ṣe ajábó aṣọ aláró aṣọ títa kan láti ìṣẹ́rẹ̀ níbi ìsopọ̀, àti bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni ìwọ yóò ṣe ni etí ìkangun aṣọ títa kejì, ni ibi ìsopọ̀ kejì. 12 Àádọ́ta ajábó ó pa lára aṣọ títa kan, àti àádọ́ta ajábó ni ó pa etí aṣọ títa ó ìsolù kejì, ajábó náà ̀kánkán ara wọn. 13 Ó ṣe àádọ́ta ìkọ́ wúrà, ó ìkọ́ wọ̀n-ọn-nì láti fi aṣọ títa kan kọ́ èkejì, bẹ́̀ ó di odidi àgọ́ kan.

14 Ìwọ ó ṣe aṣọ títa irun ewúrẹ́ láti fi ṣe ìbò sórí àgọ́ náàaṣọ títa mọ́kànlá ni ìwọ ó ṣe é. 15 Gbogbo aṣọ títa mọ́kọ̀̀kànlá náà jẹ́ ìwọ̀n kan náà, ọgbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rin fífẹ̀. 16 Ó so aṣọ títa márùn-ún pọ̀ mọ́ ara wọn se ̀kan, ó tún so mẹ́tókù mọ́ ara wọn se ̀kan. 17 Ó pa àádọ́ta ajábó ìṣẹ́ìkangun aṣọ títa apá kan, wọ́n tún pa ajábó mìíràn ìṣẹ́ìkangun aṣọ títa apá kejì. 18 Wọ́n ṣe àádọ́ta ìkọ́ idẹ láti so àgọ́ náà pọ̀ o jẹ́ ̀kan. 19 Ó ṣe ìbòrí awọ àgbò a pupa fún àgọ́ náà, àti ìbòrí awọ seali sórí rẹ̀.

20 36.20-34: Ek 26.15-29. Ó ṣe pákó igi kasia ó dúró òró fún àgọ́ náà. 21 ̀kọ̀̀kan pákó náà jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́wàá gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ kan ààbọ̀ fífẹ̀, 22 pẹ̀ìtẹ̀bọ̀ méjì ó kọjú ara wọn. Wọ́n ṣe gbogbo pákó àgọ́ náà èyí. 23 Ó ṣe ogún pákó ìhà gúúsù àgọ́ náà. 24 Ó ṣe ogójì fàdákà ihò ìtẹ̀bọ̀ lọ ìsàlẹ̀ wọn ìtẹ̀bọ̀ méjì fún pákó kọ̀̀kan, ̀kọ̀̀kan ìsàlẹ̀ ìtẹ̀bọ̀. 25 Fún ìhà kejì, ìhà àríwá àgọ́ náà, wọ́n ṣe ogún pákó 26 àti ogójì ihò ìtẹ̀bọ̀ fàdákà méjì abẹ́ pákó kọ̀̀kan. 27 Ó ṣe pákó mẹ́ìkangun, ìkangun ìhà ìwọ̀-oòrùn àgọ́ náà, 28 pákó méjì ni ìwọ ó ṣe fún igun àgọ́ náà ìhà ̀yìn. 29 igun méjèèjì yìí, pákó méjì ni ó níbẹ̀ láti ìdí orí rẹ̀ wọ́n wọ́n òrùka kan; méjèèjì bákan náà. 30 Wọ́n ó jẹ́ pákó mẹ́jọ, àti ihò ìtẹ̀bọ̀ fàdákà mẹ́rìnlélógún, méjì ìsàlẹ̀ ̀kọ̀̀kan.

31 Ó ṣe ̀igi kasia márùn-ún fún pákó ìhà kan àgọ́ náà, 32 márùn-ún fún àwọn ó ìhà kejì, márùn-ún fún pákó ó ìhà ìwọ̀-oòrùn ìkangun àgọ́ náà. 33 Wọ́n ṣe ̀àárín yóò fi jáde láti ìkangun ìkangun àárín àwọn pákó náà. 34 Ó bo àwọn pákó pẹ̀wúrà, wọ́n ṣe àwọn òrùka wúrà láti gbá ̀náà . Wọ́n tún bo ̀náà pẹ̀wúrà.

35 36.35-38: Ek 26.31-37. Ó ṣe aṣọ títa aláró, àti elése àlùkò, àti òdòdó, àti ̀gbọ̀ olókùn wẹ́wẹ́ í ṣe ọlọ́, òun ti àwọn kérúbù ni á ṣe é. 36 Wọ́n ṣe òpó igi ṣittimu mẹ́rin fún un wọ́n wọ́n pẹ̀wúrà. Wọ́n ṣe àwọn ìkọ́ wúrà fún wọn, wọ́n ihò ìtẹ̀bọ̀ fàdákà mẹ́rin mẹ́rin fún wọn. 37 Fún ẹnu-ọ̀àgọ́ náà wọ́n ṣe aṣọ títa ti aṣọ aláró, ti elése àlùkò, ti òdòdó àti ti ̀gbọ̀ olókùn dáradára a fi iṣẹ́ abẹ́rẹ́ ṣe; 38 Ó ṣe òpó márùn-ún pẹ̀ìkọ́ wọn. Ó bo orí àwọn òpó náà àti ìgbànú wọn pẹ̀wúrà, ó fi idẹ ṣe ihò ìtẹ̀bọ̀ wọn márààrún.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também