Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 27

Pẹpẹ ọrẹ ẹbọ sísun

1 27.1-8: Ek 38.1-7. "Ìwọ yóò kọ pẹpẹ igi kasia kan, ìgbọ̀nwọ́ mẹ́ta gígùn; ìhà rẹ̀ mẹ́rẹ̀̀rin jẹ́ ìwọ̀n kan, ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún gíga àti ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún fífẹ̀. 2 Ìwọ yóò ṣì ṣe ìwo orí igun mẹ́rẹ̀̀rin, àwọn ìwo náà àti pẹpẹ náà ṣe ̀kan, ìwọ yóò bo pẹpẹ náà pẹ̀idẹ. 3 Ìwọ yóò ṣe abọ́ ìtẹ́dìí rẹ láti máa gba eérú rẹ̀, àti ọkọ̀ rẹ̀, àwokòtò rẹ̀, àti fọ́̀ẹran rẹ̀, àti àwo iná rẹ̀, gbogbo ohun èlò rẹ̀ ni ìwọ yóò fi idẹ ṣe. 4 Ìwọ yóò ṣe ni wẹ́wẹ́, iṣẹ́ àwọ̀n idẹ, o ṣe òrùka idẹ igun mẹ́rẹ̀̀rin iṣẹ́ àwọ̀n náà. 5 Gbé e abẹ́ igun pẹpẹ náà, ó ìdajì pẹpẹ náà. 6 Ìwọ yóò ṣe òpó igi kasia fún pẹpẹ náà, o ó pẹ̀idẹ. 7 A ó bọ àwọn òpó náà òrùka, wọn yóò ìhà méjèèjì pẹpẹ nígbà a ú. 8 Ìwọ yóò ṣe pákó náà ni oníhò nínú. Ìwọ yóò ṣe wọ́n èyí a fihàn ́ orí òkè.

Àgbàlá

9 27.9-19: Ek 38.9-20. "Ìwọ yóò ṣe àgbàlá fún àgọ́ náà. ìhà gúúsù, ó gbọdọ̀ jẹ́ ọgọ́rùn-ún ìgbọ̀nwọ́ (mita mẹ́rìndínláàádọ́ta) gíga, ó aṣọ títa ti ̀gbọ̀ olókùn wíwẹ́, 10 pẹ̀ogún òpó àti ogún ihò ìtẹ̀bọ̀ idẹ pẹ̀ìkọ́ fàdákà, ó di àwọn òpó . 11 ìhà àríwá náà jẹ́ mita mẹ́rìndínláàádọ́ta gíga, ó aṣọ títa, pẹ̀ogun òpó àti ogún ihò ìtẹ̀bọ̀ idẹ, pẹ̀ìkọ́ fàdákà ó di àwọn òpó .

12 "ìhà ìwọ̀-oòrùn, àgbàlá náà yóò jẹ́ mita mẹ́tàlélógún fífẹ̀, ó aṣọ títa pẹ̀òpó mẹ́wàá àti ihò ìtẹ̀bọ̀ mẹ́wàá. 13 ìhà ìlà-oòrùn, ibi oòrùn ń jáde, àgbàlá náà yóò jẹ́ mita mẹ́tàlélógún fífẹ̀. 14 Aṣọ títa ìgbọ̀nwọ́ mẹ́̀́dógún gíga yóò ìhà ẹnu-ọ̀, pẹ̀òpó mẹ́ta àti ihò ìtẹ̀bọ̀ mẹ́ta, 15 àti aṣọ títa ìgbọ̀nwọ́ mẹ́̀́dógún gíga yóò ìhà kejì, pẹ̀òpó mẹ́ta àti ihò ìtẹ̀bọ̀ mẹ́ta.

16 "Àti fún ẹnu-ọ̀àgbàlá náà, pèsè aṣọ títa, mita mẹ́sàn-án gíga, ti aláró, elése àlùkò, ti òdòdó, àti ti ̀gbọ̀ olókùn wíwẹ́ a fi iṣẹ́ abẹ́rẹ́ ṣe, pẹ̀òpó mẹ́rin àti ihò ìtẹ̀bọ̀ mẹ́rin. 17 Gbogbo òpó ti ó àyíká àgbàlá náà ni a ó fi fàdákà ṣo pọ̀ àti ìkọ́, àti ihò ìtẹ̀bọ̀ idẹ. 18 Àgbàlá náà yóò jẹ́ mita mẹ́rìndínláàádọ́ta ni gíga àti mita mẹ́tàlélógún fífẹ̀, pẹ̀aṣọ títa ti ̀gbọ̀ olókùn mita méjì gíga, àti pẹ̀ihò ìtẹ̀bọ̀ idẹ. 19 Gbogbo irú iṣẹ́ ó ó ṣe, papọ̀ pẹ̀gbogbo èèkàn àgọ́ náà àti fún àgbàlá náà, ó jẹ́ idẹ.

Òróró fún ̀fìtílà

20 27.20-21: Le 24.1-4. "Ìwọ yóò pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli, wọn ó òróró olifi dáradára a gún fún , fún ìmọ́lẹ̀, fìtílà máa tàn síbẹ̀. 21 àgọ́ àjọ, lẹ́yìn òde aṣọ ìkélé ó níwájú ̀náà, Aaroni àti òun àti àwọn ọmọ rẹ̀, ni yóò tọ́rẹ̀ láti alẹ́, títí di òwúrọ̀ níwájú Olúwa: yóò di ìlànà láéláé ni ìrandíran wọn lọ́dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também