Pular para o conteúdo
Publicidade

Eksodu 8

1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "Padà tọ Farao lọ ó sọ fún un , Èyí ni Olúwa : Jẹ́ àwọn ènìyàn mi ó lọ, wọn ó à sìn mi. 2 ìwọ kọ̀ láti jẹ́ wọn ó lọ, èmi yóò fi ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ̀pọ̀lọ́ kọlu gbogbo orílẹ̀-èdè rẹ. 3 Odò Naili yóò kún fún ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ̀pọ̀lọ́. Wọn yóò gòkè ààfin rẹ, àti yàrá rẹ ni orí ibùsùn rẹ. Wọn yóò gòkè ilé àwọn ìjòyè rẹ àti ara àwọn ènìyàn rẹ, àti ibi ìdáná rẹ, àti inú ìkòkò ìyẹ̀fun rẹ. 4 Àwọn ̀pọ̀lọ́ yóò gun ara rẹ àti ara àwọn ìjòyè rẹ, àti ara gbogbo àwọn ènìyàn rẹ.’ "

5 ìgbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "Sọ fún Aaroni, ó na ọwọ́ rẹ̀ jáde pẹ̀̀orí àwọn odò kéékèèké àti odò ńlá, àti orí àwọn àbàtà ó àwọn ̀pọ̀lọ́ gòkè ilẹ̀ Ejibiti.’ "

6 ìgbà náà ni Aaroni na ọwọ́ rẹ̀ jáde orí àwọn omi Ejibiti, àwọn ̀pọ̀lọ́ , wọ́n bo gbogbo ilẹ̀. 7 Ṣùgbọ́n àwọn onídán ilẹ̀ Ejibiti ṣe bákan náà pẹ̀agbára òkùnkùn wọn. Àwọn náà ̀pọ̀lọ́ gún orí ilẹ̀ Ejibiti.

8 Farao ránṣẹ́ pe Mose àti Aaroni, ó sọ fún wọn , "Gbàdúrà Olúwa ó àwọn ̀pọ̀lọ́ wọ̀nyí kúrò lọ́dọ̀ mi àti lára àwọn ènìyàn mi, Èmi yóò jẹ́ àwọn ènìyàn rẹ ó lọ láti ẹbọ Olúwa."

9 Mose sọ fún Farao , "Jọ̀wọ́ sọ fún mi ìgbà ti èmi yóò gbàdúrà fún àti àwọn ìjòyè rẹ àti fún àwọn ènìyàn rẹ, àwọn ̀pọ̀lọ́ wọ̀nyí lọ lọ́dọ̀ rẹ àti àwọn ilé yín wọn yóò nínú odò Naili nìkan."

10 Farao , "Ni ̀la."

Mose dáhùn , "Yóò ìwọ ti sọ, ìwọ ó mọ̀ ẹni Olúwa Ọlọ́run wa. 11 Àwọn ̀pọ̀lọ́ yóò fi ìwọ àti àwọn ilé yín àti ìjòyè rẹ, àti àwọn ènìyàn rẹ sílẹ̀, wọn yóò nínú Naili nìkan."

12 Lẹ́yìn Mose àti Aaroni kúrò iwájú Farao, Mose gbé ohùn ̀bẹ̀ rẹ̀ sókè Olúwa nípa àwọn ̀pọ̀lọ́ ó ti rán Farao. 13 Olúwa ṣe gẹ́gẹ́ Mose béèrè. Àwọn ̀pọ̀lọ́ nínú ilé àti ìta, gbangba àti nínú oko. 14 Wọ́n wọn jọ ni òkìtì òkìtì gbogbo ilẹ̀ ń rùn. 15 Ṣùgbọ́n ni ìgbà Farao ìtura , ó ọkàn rẹ̀ le fetí Mose àti Aaroni gẹ́gẹ́ Olúwa ti .

Kòròrò bo ilẹ̀

16 Olúwa sọ fún Mose , "Sọ fún Aaroni, Na ̀rẹ jáde ó lu eruku ilẹ̀,’ jákèjádò gbogbo ilẹ̀ Ejibiti ni erùpẹ̀ ilẹ̀ yóò ti di kòkòrò-kantíkantí." (Kòkòrò kan ó ìyẹ́ méjì ó ṣì ń ta ni.) 17 Wọ́n ṣe bẹ́̀, nígbà Aaroni na ọwọ́ rẹ́ jáde pẹ̀̀ọwọ́ rẹ̀, ó lu eruku ilẹ̀, kòkòrò-kantíkantí lára àwọn ènìyàn àti àwọn ẹranko wọn. Gbogbo eruku jákèjádò ilẹ̀ Ejibiti ni ó di kòkòrò-kantíkantí. 18 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn onídán gbìdánwò láti da kòkòrò-kantíkantí pẹ̀agbára òkùnkùn wọn, wọn le è ṣé.

Nígbà kòkòrò-kantíkantí lára àwọn ẹranko wọn, 19 8.19: Lk 11.20.àwọn onídán sọ fún Farao , "Ìka Ọlọ́run ni èyí." Ṣùgbọ́n àyà Farao yigbì, fetísílẹ̀, gẹ́gẹ́ Olúwa ti sọ.

Àwọn eṣinṣin bo ilẹ̀

20 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose , "Lọ òwúrọ̀ kùtùkùtù o ko Farao lójú ó ṣe ń lọ odò, o sọ fún un , Èyí ni Olúwa sọ: Jẹ́ àwọn ènìyàn mi ó lọ, wọn ó à sìn Mi. 21 ìwọ jẹ́ àwọn ènìyàn Mi ó lọ, èmi yóò rán ̀pọ̀lọpọ̀ eṣinṣin ara rẹ àti ara àwọn ìjòyè rẹ, àti ara àwọn ènìyàn rẹ̀, àwọn ilẹ̀ rẹ̀. Gbogbo ilé àwọn ará Ejibiti ni yóò kún fún eṣinṣin àti orí ilẹ̀ wọ́n pẹ̀.

22 " Ṣùgbọ́n ni ọjọ́ náà, Èmi yóò ya ilẹ̀ Goṣeni sọ́tọ̀, níbi àwọn ènìyàn mi ń gbé, ̀wọ́ eṣinṣin kankan ki yóò ibẹ̀. ìwọ ó mọ̀ , Èmi ni Olúwa, mo ni ilẹ̀ yìí. 23 Èmi yóò pààlà sáàárín àwọn ènìyàn mi àti àwọn ènìyàn rẹ. Àwọn iṣẹ́ ìyanu yìí yóò ṣẹlẹ̀ ni ̀la.’ "

24 Olúwa ṣe èyí. ̀pọ̀lọpọ̀ eṣinṣin ya wọ ààfin Farao àti ilé àwọn ìjòyè rẹ̀. Gbogbo ilẹ̀ Ejibiti bàjẹ́ pẹ̀̀wọ́ eṣinṣin wọ̀n-ọn-nì.

25 Nígbà náà ni Farao ránṣẹ́ pe Mose àti Aaroni, ó fún wọn , "máa lọ ẹbọ Ọlọ́run yín ilẹ̀ yìí."

26 Ṣùgbọ́n Mose sọ , "Èyí tọ́, ẹbọ a ó Olúwa Ọlọ́run wa yóò jẹ́ ohun ìríra àwọn ará ilẹ̀ Ejibiti. a ṣe ìrúbọ ti yóò jẹ́ ìríra ni ojú wọn ṣé wọn, ó sọ òkúta ? 27 A gbọdọ̀ lọ ni ìrìn ọjọ́ mẹ́ta inú aginjù láti ẹbọ Olúwa Ọlọ́run gẹ́gẹ́ ó ti pàṣẹ fún wa."

28 Nígbà náà ni Farao , "Èmi yóò jẹ́ ki lọ ẹbọ Olúwa Ọlọ́run yín nínú aginjù, ṣùgbọ́n gbọdọ̀ rìn jìnnà . gbàdúrà fún mi."

29 Mose dáhùn ó , "èmi ti kúrò ̀dọ̀ rẹ, èmi yóò gbàdúrà Olúwa, àwọn ̀wọ́ eṣinṣin yóò fi Farao, àwọn ìjòyè rẹ, àti àwọn ènìyàn rẹ sílẹ̀ ̀la ṣùgbọ́n ǹjẹ́ ìdánilójú wa Farao tún ni lo ̀tàn láti jẹ́ àwọn ènìyàn ó lọ ẹbọ Olúwa."

30 Nígbà náà ni Mose kúrò ni ̀dọ̀ Farao, ó gbàdúrà Olúwa; 31 Olúwa ṣe gẹ́gẹ́ Mose ti béèrè. Àwọn ̀wọ́ eṣinṣin kúrò lára Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀ àti lára àwọn ènìyàn rẹ̀ pẹ̀, eṣinṣin kan ṣẹ́. 32 Ṣùgbọ́n ni àkókò yìí náà, Farao ọkàn rẹ le, jẹ́ àwọn ènìyàn ó lọ.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também