Pular para o conteúdo
Publicidade

Comunhão com Deus

Por Bíblia Online

A comunhão com Deus é o propósito supremo da existência humana. Fomos criados para viver em intimidade com o Criador — e em Cristo, esse acesso é plenamente restaurado.

Em comunhão com Deus

Deus é fiel, pelo qual fostes chamados à comunhão de seu Filho. A comunhão com Deus é dom da graça e fruto da redenção.

Ọlọ́run, nípasẹ̀ ẹni ti a yín sínú ìdàpọ̀ pẹ̀Ọmọ rẹ̀ Jesu Kristi Olúwa wa, jẹ́ Olóòtítọ́.

Ṣé ̀yin tilẹ̀ mọ̀ tẹmpili Ọlọ́run ni ̀yin jẹ́? Àti pẹ̀pe ̀Ọlọ́run ń gbé inú yín?

Ara jẹ́ ̀kan ó àwọn ̀púpọ̀, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ̀ara ó pọ̀ wọ̀nyí ni ó papọ̀ láti jẹ́ ara kan ṣoṣo. Bákan náà ni ó pẹ̀ara Kristi í ṣe ìjọ.

Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa, àti ìfẹ́ Ọlọ́run, àti ìdàpọ̀ ti Èmí Mímọ́, ó pẹ̀gbogbo yín.

Ìrẹ́pọ̀ kín ni tẹmpili Ọlọ́run pẹ̀òrìṣà? Nítorí ̀yin tẹmpili Ọlọ́run alààyè; gẹ́gẹ́ Ọlọ́run ti :

"Èmi á gbé inú wọn,

èmi o máa rìn láàrín wọn,

èmi ó jẹ́ Ọlọ́run wọn,

wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi."

Nítorí náà ẹnìkan nínú Kristi, ó di ̀tuntun: ohun àtijọ́ ti kọjá lọ; kíyèsi i, ohun tuntun ti . Ohun gbogbo ti ̀dọ̀ Ọlọ́run , ẹni ó tipasẹ̀ Jesu Kristi wa làjà sọ́dọ̀ ara rẹ̀, ó ti fi iṣẹ́ ìránṣẹ́ ìlàjà fún wa. Èyí ni , Ọlọ́run nínú Kristi, ó ń aráyé làjà sọ́dọ̀ ara rẹ̀, ka ìrékọjá wọn wọn lọ́rùn; ó ti fi ̀rọ̀ ìlàjà wa lọ́wọ́.

Presença divina

Eis que estou à porta e bato. O Senhor fez sua morada entre nós — e toda a criação é convidada à comunhão eterna.

Kíyèsi i, èmi dúró ni ẹnu ìlẹ̀kùn, èmi ń kànkùn, ẹnikẹ́ni gbọ́ ohun mi, ó ṣí ìlẹ̀kùn, èmi yóò wọlé tọ̀ ́ , èmi yóò máa a jẹun, àti òun pẹ̀mi.

Mo gbọ́ ohùn ńlá kan láti orí ìtẹ́ náà , ń , "Kíyèsi i, àgọ́ Ọlọ́run pẹ̀àwọn ènìyàn, òun ó máa wọn gbé, wọn ó máa jẹ́ ènìyàn rẹ̀, àti Ọlọ́run tìkára rẹ̀ yóò pẹ̀wọn, yóò máa jẹ́ Ọlọ́run wọn.

Nígbà náà ni èmi yóò máa gbé láàrín àwọn ọmọ Israẹli, èmi yóò máa ṣe Ọlọ́run wọn.

Nítorí níbi ti ènìyàn méjì tàbí mẹ́ta ara jọ ni orúkọ mi, èmi yóò láàrín wọn níbẹ̀."

Jesu gbàdúrà fún gbogbo onígbàgbọ́

"í ṣe kìkì àwọn wọ̀nyí ni mo ń gbàdúrà fún, ṣùgbọ́n fún àwọn pẹ̀yóò gbà gbọ́ nípa ̀rọ̀ wọn. gbogbo wọn ó jẹ́ ̀kan; gẹ́gẹ́ ìwọ, Baba, ti jẹ́ nínú mi, àti èmi nínú rẹ, àwọn pẹ̀ó jẹ́ ̀kan nínú wa, ayé ó gbàgbọ́ , ìwọ ni ó rán mi. Ògo ìwọ ti fi fún mi ni èmi ti fi fún wọn; wọn ó jẹ́ ̀kan, gẹ́gẹ́ àwa ti jẹ́ ̀kan. Èmi nínú wọn, àti ìwọ nínú mi, a ṣe wọ́n ̀kan; ayé ó mọ̀ , ìwọ ni ó rán mi, àti ìwọ fẹ́ràn wọn gẹ́gẹ́ ìwọ ti fẹ́ràn mi.

Viver na comunhão

Quem permanece nele e ele no Senhor, esse dá muito fruto. A comunhão com Deus produz transformação e alegria.

Ẹni ó pa òfin rẹ̀ mọ́ ń gbé inú rẹ̀, àti òun nínú rẹ̀. Àti nípa èyí ni àwa mọ̀ ó ń gbé inú wa, nípa ̀ó fi fún wa.

Àwa mọ̀ Ọmọ Ọlọ́run , ó fi òye fún wa, àwa mọ ẹni í ṣe òtítọ́, àwa ń bẹ nínú ẹni í ṣe òtítọ́, àní, nínú Ọmọ rẹ̀, Jesu Kristi. Èyí ni Ọlọ́run òtítọ́, àti ìyè àìnípẹ̀kun.

Nípa èyí ni àwa mọ̀ àwa ń gbé inú rẹ̀, àti Òun nínú wa, nítorí ó ti fi ̀rẹ̀ fún wa.

Ìfẹ́ Ọlọ́run àti ti àwa

Olùfẹ́, jẹ́ a fẹ́ràn ara wa, nítorí ìfẹ́ ti ̀dọ̀ Ọlọ́run ; àti gbogbo ẹni ó ìfẹ́, a i nípa ti Ọlọ́run, ó mọ Ọlọ́run.

Àwa ń sọ fún yín, èyí àwa ti , àwa ti gbọ́, ̀yin pẹ̀ó ìdàpọ̀ pẹ̀wa. Nítòótọ́ ìdàpọ̀ wa ń bẹ pẹ̀Baba àti pẹ̀ọmọ rẹ̀, Jesu Kristi.

Àwọn ọmọ Ọlọ́run

Àti nísinsin yìí, ̀yin ọmọ mi ̀wọ́n, máa gbé inú rẹ̀, nígbà òun ó farahàn, a ni ìgboyà níwájú rẹ̀, ojú níwájú rẹ̀ ni ìgbà wíwá rẹ̀.

Àlàáfíà àti ayọ̀

Nítorí náà, níwọ̀n ìgbà a ti wa láre nípa ìgbàgbọ́, àwa àlàáfíà lọ́dọ̀ Ọlọ́run nípasẹ̀ Olúwa wa Jesu Kristi. Nípasẹ̀ ẹni àwa ti ̀gbà nípa ìgbàgbọ́ inú oore-ọ̀fẹ́ yìí nínú èyí àwa gbé dúró. Àwa ń yọ̀ nínú ìrètí ògo Ọlọ́run.

jẹ́ a fi òtítọ́ ọkàn súnmọ́ tòsí ni ̀kún ìgbàgbọ́, a wẹ ọkàn wa mọ́ kúrò nínú ̀ọkàn búburú, a fi omi mímọ́ wẹ ara wa .

Nítorí náà, tẹríba fún Ọlọ́run. kọ ojú ìjà èṣù, òun ó kúrò lọ́dọ̀ yín. súnmọ́ Ọlọ́run, òun ó súnmọ́ yín. wẹ ọwọ́ yín mọ́, ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀; ṣe ọkàn yín mímọ́, ̀yin oníyèméjì.

Seja o primeiro

Este artigo te tocou? Faça uma oração!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.