Pular para o conteúdo
Publicidade

Coração

Por Bíblia Online

O coração é o centro do ser humano — sede dos pensamentos, emoções e decisões. A Bíblia ensina a guardar, purificar e render o coração a Deus como oferta viva.

Guardar o coração

Sobre tudo o que se deve guardar, guarda o teu coração, porque dele procedem as fontes da vida e de toda decisão.

Ju gbogbo nǹkan tókù lọ, pa ọkàn rẹ mọ́,

nítorí òun ni orísun ìyè.

Ju gbogbo nǹkan tókù lọ, pa ọkàn rẹ mọ́,

nítorí òun ni orísun ìyè.

Gbẹ́kẹ̀Olúwa pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ

ṣe sinmi òye ara à rẹ.

Gbẹ́kẹ̀Olúwa pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ

ṣe sinmi òye ara à rẹ.

Mọ̀ ́n gbogbo ̀rẹ

òun yóò máa tọ́ ipa ̀rẹ.

Àwọn àǹfààní ọgbọ́n mìíràn

Ọmọ mi, ṣe gbàgbé ̀kọ́ mi.

Ṣùgbọ́n pa òfin mi mọ́ ọkàn rẹ.

Nítorí ọjọ́ gígùn, ̀gígùn, àti àlàáfíà,

ni wọn yóò fi kùn un fún .

ṣe jẹ́ ìfẹ́ àti òtítọ́ ṣíṣe fi ́ sílẹ̀ láéláé

so wọ́n mọ́ ọrùn rẹ,

kọ wọ́n wàláà àyà rẹ.

Nígbà náà ni ìwọ yóò ojúrere àti orúkọ rere

ojú Ọlọ́run àti lójú ènìyàn.

Ọkàn ó lálàáfíà fi ìyè ọjọ́ ayé gùn fún ara,

ṣùgbọ́n ìlara egungun jẹrà.

Ẹni ó gbọ́n nínú ọkàn rẹ̀ máa ń gba àṣẹ,

ṣùgbọ́n ètè wérewère yóò parun.

Coração puro

Cria em mim um coração puro, ó Deus. Ensina-me a contar meus dias para que tenha um coração sábio.

ọkàn mímọ́ inú mi, Ọlọ́run,

o tún ̀dídúró ṣinṣin ṣe sínú mi.

ọkàn mímọ́ inú mi, Ọlọ́run,

o tún ̀dídúró ṣinṣin ṣe sínú mi.

Kọ́ wa a ti ń kaye ọjọ́ wa dáradára,

àwa ba à fi ọkàn wa sípa ọgbọ́n.

Jẹ́ ̀rọ̀ ẹnu mi àti àṣàrò ọkàn mi

ó jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà ojú rẹ,

Ìwọ Olúwa àpáta mi, àti Olùdáǹdè mi.

Jẹ́ alágbára, yóò yín àyà le

gbogbo ̀yin ó dúró de Olúwa.

Ṣe inú dídùn Olúwa;

òun yóò fún ìfẹ́ inú rẹ̀.

ó fi fún gẹ́gẹ́ bi ti èrò ọkàn rẹ

ó gbogbo ìmọ̀ rẹ ṣẹ.

Ìbùkún ni fún àwọn ẹni ń pa òfin rẹ̀ mọ́

wọn ń a pẹ̀gbogbo ọkàn wọn.

Èmi yóò yìn ́ pẹ̀ọkàn ìdúró ṣinṣin

èmi ti kọ́ òfin òdodo rẹ̀.

Èmi pẹ̀gbogbo ọkàn mi

ṣe jẹ́ èmi yapa kúrò nínú àṣẹ rẹ.

Buscar a Deus de coração

Amarás ao Senhor teu Deus de todo o coração. A busca sincera leva ao encontro; o coração dividido leva à ruína.

Jesu dáhùn , " Fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ, gbogbo ̀rẹ àti gbogbo inú rẹ.

Jesu dáhùn , " Fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ, gbogbo ̀rẹ àti gbogbo inú rẹ.

Nítorí ibi ìṣúra yín níbẹ̀ náà ni ọkàn yín yóò pẹ̀.

Lóòótọ́ ni fún un yín, ẹnikẹ́ni fún òkè Ṣídìí, gbé ara rẹ sọ sínú Òkun,ti ṣe iyèméjì nínú ọkàn rẹ̀ ṣùgbọ́n ó gbàgbọ́ ohun òun yóò ṣẹ, yóò bẹ́̀ fún un.

Ọkàn ènìyàn kún fún ̀tàn ju ohun gbogbo lọ,

ó kọjá ohun a wòsàn.

Ta ni èyí ?

Ọkàn ènìyàn kún fún ̀tàn ju ohun gbogbo lọ,

ó kọjá ohun a wòsàn.

Ta ni èyí ?

"Èmi Olúwa ń wo ọkàn

àti èrò inú ọmọ ènìyàn,

láti san èrè iṣẹ́ rẹ̀ fún un gẹ́gẹ́ ̀rẹ̀,

àti gẹ́gẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀."

̀yin yóò mi, ̀yin fi gbogbo ọkàn yín mi: ̀yin yóò mi ni Olúwa Ọlọ́run .

Ṣùgbọ́n ṣọ́ra gidigidi láti pa àṣẹ àti òfin Mose ìránṣẹ́ Olúwa fi fún yin mọ́. Láti fẹ́ràn Olúwa Ọlọ́run yín, láti rìn nínú gbogbo ̀rẹ̀, láti gbọ́rọ̀ àṣẹ rẹ̀, láti dìímú ṣinṣin àti láti sìn ín pẹ̀gbogbo ọkàn yín àti gbogbo àyà yín."

Èmi yóò fún wọn ̀kankan; èmi yóò fi ̀tuntun sínú wọn, Èmi yóò ọkàn òkúta kúrò lára wọn, èmi yóò fún wọn ọkàn rọ̀ ara ẹran.

Èmi yóò fún yín ni ọkàn tuntun, èmi yóò fi ̀tuntun sínú yín; Èmi yóò ọkàn òkúta kúrò nínú yín, èmi yóò fi ọkàn ẹran fún yín.

Conhecer o coração

O homem olha para a aparência, mas o Senhor olha para o coração. Deus conhece os segredos mais profundos.

Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Samuẹli , "ṣe wo ti ìrísí rẹ̀ tàbí ti gíga rẹ̀, nítorí èmi ti kọ̀ ́ sílẹ̀. Olúwa í wo ohun ènìyàn máa ń . Ènìyàn máa ń wo òde ara ṣùgbọ́n Olúwa máa ń wo ọkàn."

Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Samuẹli , "ṣe wo ti ìrísí rẹ̀ tàbí ti gíga rẹ̀, nítorí èmi ti kọ̀ ́ sílẹ̀. Olúwa í wo ohun ènìyàn máa ń . Ènìyàn máa ń wo òde ara ṣùgbọ́n Olúwa máa ń wo ọkàn."

omi ń ṣe àfihàn ojú, nígbà a ó

bẹ́̀ ni ọkàn ènìyàn ń ṣe àfihàn ènìyàn.

Ọkàn ó túká jẹ́ oògùn gidi,

ṣùgbọ́n ọkàn ó bàjẹ́ a máa egungun gbẹ.

Fi ohun gbogbo o ṣe Olúwa lọ́wọ́,

èrò rẹ yóò ṣe é ṣe.

̀ṣọ́ yín ṣe jẹ́ ̀ṣọ́ òde, irun dídì, àti wúrà lílò, tàbí ti aṣọ wíwọ̀; ṣùgbọ́n ó jẹ́ ẹni ó fi ara sin ọkàn, nínú ̀ṣọ́ àìdíbàjẹ́ ti ̀ìrẹ̀lẹ̀ àti ̀tútù, èyí i ṣe iyebíye níwájú Ọlọ́run.

olúkúlùkù ènìyàn ṣe gẹ́gẹ́ ó ti pinnu ọkàn rẹ̀; í ṣe àfi ìkùnsínú ṣe, tàbí ti àìgbọdọ̀ ṣe; nítorí Ọlọ́run fẹ́ onínúdídùn ọlọ́rẹ.

Ṣùgbọ́n ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run , ̀yin ti jẹ́ ẹrú ̀ṣẹ̀ , ̀yin jẹ́ olùgbọ́ran láti ọkàn àpẹẹrẹ ̀kọ́ èyí Ọlọ́run fi yín lọ́wọ́.

ó fi ọkàn yín balẹ̀ àìlábùkù nínú ìwà mímọ́ níwájú Ọlọ́run àti Baba wa. Nígbà náà, ó ìgboyà láti dúró níwájú rẹ̀ láìṣẹ̀, ọjọ́ Olúwa wa Jesu Kristi yóò padà pẹ̀àwọn ó jẹ́ tirẹ̀.

ṣe ọkàn yín le,

ìgbà ìṣọ̀tẹ̀,

i ọjọ́ ìdánwò aginjù,

Seja o primeiro

Este artigo te tocou? Faça uma oração!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.