Publicidade

Honestidade

Por Bíblia Online

A honestidade é virtude cristã fundamental. Deus é Deus de verdade e nos chama a viver com integridade, transparência e retidão em todos os nossos relacionamentos e negócios.

Integridade diante de Deus

O Senhor abomina a balança falsa, mas o peso justo é seu prazer. A integridade dos justos os guia pelos caminhos retos.

Olúwa kórìíra òsùwọ̀n èké,

ṣùgbọ́n òsùwọ̀n òtítọ́ jẹ́ inú dídùn un rẹ̀.

Òtítọ́ inú ẹni dídúró ṣinṣin ń ṣe amọ̀rẹ̀,

ṣùgbọ́n aláìṣòótọ́ yóò parun nípasẹ̀ àìṣòótọ́ wọn.

Òtítọ́ inú ẹni dídúró ṣinṣin ń ṣe amọ̀rẹ̀,

ṣùgbọ́n aláìṣòótọ́ yóò parun nípasẹ̀ àìṣòótọ́ wọn.

Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ òdodo àti ìdájọ́,

àti àìṣègbègbogbo ipa ̀rere.

Ṣíṣe ohun ó dára ó tọ̀

ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà Olúwa ju ẹbọ lọ.

Jẹ́ ojú rẹ máa wo iwájú,

jẹ́ ìwo ojú rẹ máa wo ̀kánkán iwájú rẹ á.

ṣùgbọ́n àwa kọ gbogbo ohun ìkọ̀kọ̀ ó ìtìjú sílẹ̀, àwa rìn ̀tàn, bẹ́̀ ni àwa fi ọwọ́ ̀tàn ̀rọ̀ Ọlọ́run; ṣùgbọ́n nípa fífi òtítọ́ hàn, àwa ń fi ara wa le ̀ọkàn olúkúlùkù ènìyàn lọ́wọ́ níwájú Ọlọ́run.

Àwa ń gbèrò ohun rere, í ṣe níwájú Olúwa nìkan, ṣùgbọ́n níwájú ènìyàn pẹ̀.

Praticar a honestidade

Falai a verdade, pagai o que deveis, não negueis ao próximo o bem. A honestidade prática é testemunho do evangelho.

ṣe purọ́ fún ara yín, níwọ̀n ìgbà ti bọ́ ògbólógbòó ara yín pẹ̀ìṣe rẹ̀ sílẹ̀,

san ohun ó tọ́ fún ẹni gbogbo: owó òde fún ẹni owó òde í ṣe tirẹ̀: owó bodè fún ẹni owó bodè í ṣe tirẹ̀: ̀fún ẹni ̀í ṣe tirẹ̀; ọlá fún ẹni ọlá í ṣe tirẹ̀.

Nítorí ìdí èyí, san owó òde pẹ̀, nítorí ìránṣẹ́ Ọlọ́run ni wọ́n, èyí náà ni wọ́n ń bojútó nígbà gbogbo.

ṣe fi búburú san búburú fún ẹnikẹ́ni. pèsè ohun ó tọ́ níwájú gbogbo ènìyàn.

ṣe fa ọwọ́ ìre sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ àwọn ṣe tìrẹ,

nígbà ó ìkápá rẹ láti ṣe ohun kan.

Ó sàn ó kéré pẹ̀òdodo

ju èrè púpọ̀ pẹ̀èrú lọ.

Ìṣúra a kójọ nípa ìwà búburú èrè,

ṣùgbọ́n òdodo a máa gbani lọ́wọ́ ikú.

Confissão e transparência

Confessai as vossas ofensas uns aos outros. Quem confessa e deixa o pecado encontra misericórdia e restauração.

Ẹni ó bo ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ yóò ṣe rere,

ṣùgbọ́n ẹni ó jẹ́wọ́ ó kọ̀ wọ́n sílẹ̀ máa ń àánú gbà.

jẹ́wọ́ ̀ṣẹ̀ yín fún ara yín, máa gbàdúrà fún ara yín, a yín láradá. Iṣẹ́ àdúrà olódodo ń ṣe agbára púpọ̀.

Ṣùgbọ́n ju ohun gbogbo lọ, ará mi, ṣe ìbúra, ìbá à ṣe fífi ̀run búra, tàbí ilẹ̀, tàbí ìbúra-kíbúra mìíràn. Ṣùgbọ́n jẹ́ "Bẹ́̀ ni" yín jẹ́ bẹ́̀ ni; àti "Bẹ́̀ kọ́" yín jẹ́ bẹ́̀ kọ́; ba à bọ́ sínú ̀bi.

Ṣùgbọ́n ọgbọ́n ó ti òkè jẹ́ mímọ́ àkọ́kọ́, ti àlàáfíà, àti ti ìrẹ̀lẹ̀, í í ṣòro láti bẹ̀, ó kún fún àánú àti fún èso rere, í ṣe ojúsàájú, a máa sọ òtítọ́.

àwa àwa ìdàpọ̀ pẹ̀rẹ̀, àwa ń rìn nínú òkùnkùn, àwa ń ṣèké, àwa gbé nínú òtítọ́.

̀yin ọmọ mi, ṣe jẹ́ a fi ̀rọ̀ tàbí ahọ́n fẹ́ràn, ṣe ni ìṣe àti òtítọ́.

Coração puro

Bem-aventurados os puros de coração, porque verão a Deus. A honestidade começa no interior e se manifesta nas ações.

Alábùkún fún ni àwọn ọlọ́kàn mímọ́,

nítorí wọn yóò Ọlọ́run.

Ìwọ dákẹ́ jẹ́́ níwájú Olúwa,

o fi sùúrù dúró é;

ṣe ṣe ìkanra nítorí àwọn ń rere ̀wọn,

nítorí ọkùnrin náà ti èrò búburú ṣẹ.

Ènìyàn rere fi ojúrere hàn,

a wínni;

ìmòye ni yóò máa fi la ̀iṣẹ́ rẹ̀.

Ṣaápọn láti fi ara rẹ̀ hàn níwájú Ọlọ́run bi ẹni ó yege àti òṣìṣẹ́ láti tijú, ó ń pín ̀rọ̀ òtítọ́ ó ti yẹ.

Àtùpà lórí tábìlì

"ẹnikẹ́ni, nígbà ó tán fìtílà tan, yóò fi ohun èlò ó mọ́lẹ̀, tàbí yóò gbé e sábẹ́ àkéte; ṣe ó gbé e ka orí ̀fìtílà, àwọn ń wọ ilé ìmọ́lẹ̀.

A ènìyàn búburú nípasẹ̀ ̀rọ̀ ̀ṣẹ̀ rẹ̀

ṣùgbọ́n olódodo bọ́ kúrò lọ́wọ́ ìdààmú.

Ẹni ó jẹ́ ajẹ́rìí òtítọ́ jẹ́rìí ohun ojú rẹ̀

ṣùgbọ́n ajẹ́rìí èké máa ń parọ́.

Aláyídáyidà ènìyàn ìjà sílẹ̀

olófòófó a máa pín ̀rẹ́ kòríkòsùn .

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-