Publicidade

1 Coríntios 11

24 Lẹ́yìn ìgbà ó ti dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run fún àkàrà náà tan, ó ú, ó fi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó , "gbà jẹ, èyí ara mi a fi fún un yín. máa ṣe eléyìí ni rántí mi." 25 11.25: 2Kọ 3.6; Lk 22.20.Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ lẹ́yìn oúnjẹ alẹ́, ó ago wáìnì, ó , "Ago yìí ni májẹ̀tuntun nínú ̀jẹ̀ mi, máa ṣe èyí, nígbàkígbà ti ̀yìn ń mu ú, ìrántí mi." 26 11.26: 1Kọ 4.5.Nítorí nígbàkígbà ń jẹ lára àkàrà yìí, ǹ mu nínú ago yìí, ni tún sọ nípa ikú Olúwa. máa ṣe eléyìí títí yóò fi padà .

27 Nítorí náà ẹnikẹ́ni jẹ lára àkàrà yìí, ń mu nínú ago Olúwa yìí, ̀bójúmu, yóò jẹ̀bi ̀ṣẹ̀ ara àti ̀jẹ̀ Olúwa. 28 Ìdí nìyìí ó fi yẹ ènìyàn yẹ ara rẹ̀ dáradára ó jẹ lára àkàrà án àti ó mu nínú ago náà.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-