Publicidade

1 Coríntios 13

Ìfẹ́

1 èmi tilẹ̀ sọ oríṣìíríṣìí èdè ènìyàn àti ti angẹli, n ìfẹ́, mo kàn ń pariwo ago lásán ni tàbí i kimbali olóhùn gooro. 2 mo ̀bùn ìsọtẹ́lẹ̀, mo òye gbogbo ohun ìjìnlẹ̀, àti gbogbo ìmọ̀, mo ni gbogbo ìgbàgbọ́ bẹ́̀ mo ṣí àwọn òkè ńlá nídìí, èmi ìfẹ́, èmi jẹ nǹkan kan. 3 mo fi gbogbo nǹkan mo tọrẹ fún àwọn aláìní, mo fi ara mi fún ni láti sùn ṣùgbọ́n n ìfẹ́, èrè kan fún mi.

4 Ìfẹ́ a máa sùúrù, ìfẹ́ a máa ṣeun, ìfẹ́ í ṣe ìlara, ìfẹ́ í fẹ̀, ìfẹ́ í sọ̀rọ̀ ìgbéraga. 5 Ìfẹ́ í hùwà àìtọ́, í ohun ara rẹ̀ nìkan. Ìfẹ́ í bínú fùfù, ìfẹ́ í fi búburú ọmọ ẹnìkejì sínú. 6 Inú ìfẹ́ í dùn àìṣòótọ́. Ṣùgbọ́n inú rẹ̀ a máa dùn nígbà gbogbo. 7 A máa faradà ohun gbogbo òtítọ́, a máa gba ohun gbogbo gbọ́, a máa retí ohun gbogbo, a máa fàyàrán ohun gbogbo.

8 Ìfẹ́ í kùnà láé, í í yẹ̀ ṣùgbọ́n ó ṣe ìsọtẹ́lẹ̀ ni, wọn yóò dópin, ó ṣe ̀bùn ahọ́n ni, wọn yóò dákẹ́, ó ṣe ìmọ̀ ni yóò di asán. 9 Nítorí àwa mọ̀ apá kan, àwa sọtẹ́lẹ̀ apá kan. 10 Ṣùgbọ́n nígbà èyí ti o , èyí í ṣe apá kan yóò dópin. 11 Nígbà ni èwe, èmi á máa sọ̀rọ̀ bi èwe, èmi a máa mòye èwe, èmi a máa gbèrò èwe. Ṣùgbọ́n nígbà di ọkùnrin tán, mo fi ìwà èwe sílẹ̀. 12 Nítorí nísinsin yìí àwa ń ríran bàìbàì nínú dígí; nígbà náà a ó í lójúkojú. Nísinsin yìí mọ̀ apá kan; nígbà náà èmi o mọ̀ lẹ́kùnrẹ́rẹ́, kódà mo ti mọ̀ pẹ̀.

13 Ǹjẹ́ nísinsin yìí àwọn nǹkan mẹ́ta wọ̀nyí dúró: ìgbàgbọ́, ìrètí, àti ìfẹ́. Ṣùgbọ́n èyí o tóbi nínú wọn ni ìfẹ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-