Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Coríntios 15

22 15.22: Ro 5.14-18.Nítorí gbogbo ènìyàn ti nínú Adamu, bẹ́̀ a ó sọ gbogbo ènìyàn alààyè nínú Kristi. 23 15.23: 1Tẹ 2.19.Ṣùgbọ́n olúkúlùkù ènìyàn ipá tirẹ̀: Kristi àkọ́; lẹ́yìn èyí àwọn ó jẹ́ Kristi ni wíwá rẹ̀. 24 Nígbà náà ni òpin yóò , nígbà ó ti fi ìjọba fún Ọlọ́run Baba, nígbà ó pa gbogbo àṣẹ àti gbogbo ọlá àti agbára run. 25 15.25: Sm 110.1.Nítorí ti òun gbọdọ̀ ti jẹ ọba òun to fi gbogbo àwọn ̀rẹ̀ abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.

Veja também