Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Pedro 4

2 ̀yin ṣe fi ìgbà ayé yín ìyókù nínú ara mọ́ ìfẹ́kúfẹ̀́ ènìyàn ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run. 3 Nítorí ìgbà ó ti kọjá ti fún ṣíṣe ìfẹ́ àwọn aláìkọlà, rínrìn nínú ìwà wọ̀bìà, ìfẹ́kúfẹ̀́, ọtí àmupara, ìréde òru, kíkó ̀gbẹ́ ̀mùtí, àti ìbọ̀rìṣà í ṣe ohun ìríra. 4 Èyí ó wọ́n lẹ́nu ̀yin ba wọn súré sínú irú àṣejù ìwà wọ̀bìà wọ́n, wọ́n ń sọ̀rọ̀ yín búburú. 5 Àwọn ẹni yóò jíyìn fún ẹni ó ti múra láti ṣe ìdájọ́ alààyè àti òkú. 6 Nítorí èyí a ṣe wàásù ìyìnrere fún àwọn òkú, a ṣe ìdájọ́ wọn gẹ́gẹ́ ènìyàn nípa ti ara, ṣùgbọ́n wọ́n láààyè si Ọlọ́run nípa ̀.

7 Ṣùgbọ́n òpin ohun gbogbo dẹ̀dẹ̀; nítorí náà ̀yin àìrékọjá, máa ṣọ́ra nínú àdúrà.

Veja também