Publicidade

1 Pedro 4

Ìgbé ayé fún Ọlọ́run

1 Ǹjẹ́ Kristi ti jìyà fún wa nípa ti ará, irú kan náà ni ̀yin fi hámọ́ra; nítorí ẹni ó ti jìyà nípa ti ara, ó ti bọ́ lọ́wọ́ ̀ṣẹ̀. 2 ̀yin ṣe fi ìgbà ayé yín ìyókù nínú ara mọ́ ìfẹ́kúfẹ̀́ ènìyàn ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run. 3 Nítorí ìgbà ó ti kọjá ti fún ṣíṣe ìfẹ́ àwọn aláìkọlà, rínrìn nínú ìwà wọ̀bìà, ìfẹ́kúfẹ̀́, ọtí àmupara, ìréde òru, kíkó ̀gbẹ́ ̀mùtí, àti ìbọ̀rìṣà í ṣe ohun ìríra. 4 Èyí ó wọ́n lẹ́nu ̀yin ba wọn súré sínú irú àṣejù ìwà wọ̀bìà wọ́n, wọ́n ń sọ̀rọ̀ yín búburú. 5 Àwọn ẹni yóò jíyìn fún ẹni ó ti múra láti ṣe ìdájọ́ alààyè àti òkú. 6 Nítorí èyí a ṣe wàásù ìyìnrere fún àwọn òkú, a ṣe ìdájọ́ wọn gẹ́gẹ́ ènìyàn nípa ti ara, ṣùgbọ́n wọ́n láààyè si Ọlọ́run nípa ̀.

7 Ṣùgbọ́n òpin ohun gbogbo dẹ̀dẹ̀; nítorí náà ̀yin àìrékọjá, máa ṣọ́ra nínú àdúrà. 8 Ju gbogbo rẹ̀ lọ, ìfẹ́ ó gbóná láàrín ara yín, nítorí ìfẹ́ ni ń bo ̀pọ̀lọpọ̀ ̀ṣẹ̀ mọ́lẹ̀. 9 máa ṣe ara yín ni àlejò láìsí ìkùnsínú. 10 olúkúlùkù ti ̀bùn gbà, bẹ́̀ ni máa ṣe ìpín fún ni rẹ̀ láàrín ara yín, ìríjú rere onírúurú oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run. 11 ẹnikẹ́ni ba ń sọ̀rọ̀, o máa sọ ̀rọ̀ Ọlọ́run, ẹnikẹ́ni ń ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́, ó ṣe é agbára Ọlọ́run fi fún un, a máa yin Ọlọ́run lógo ohun gbogbo nípa Jesu Kristi, ẹni ògo àti ìjọba fún láé àti láéláé. Àmín.

Jíjìyà fun jíjẹ́ onígbàgbọ́

12 Olùfẹ́, ṣe ka ìdánwò gbígbóná ti ń bẹ láàrín yín láti dán yín bi ẹni ohun àjèjì ni ó yín. 13 Ṣùgbọ́n níwọ̀n ̀yin jẹ́ alábápín ìyà Kristi, máa yọ̀, ̀yin yọ ayọ̀ púpọ̀ nígbà a fi ògo rẹ̀ hàn. 14 a gàn yín nítorí orúkọ Kristi, ẹni ìbùkún ni yín: nítorí ̀Ògo àti ti Ọlọ́run yín. 15 Ṣùgbọ́n jẹ́ ẹnikẹ́ni nínú yín jìyà apànìyàn, tàbí olè, tàbí olùṣe búburú, tàbí ẹni ń tojú bọ̀ ̀ràn ẹlòmíràn. 16 Ṣùgbọ́n ó jìyà Kristiani ojú ṣe í, ṣùgbọ́n ó kúkú yin Ọlọ́run lógo nítorí ti o orúkọ yìí. 17 Nítorí ti ìgbà náà , ìdájọ́ yóò bẹ̀rẹ̀ láti ilé Ọlọ́run , ó tètè ̀dọ̀ wa bẹ̀rẹ̀, ìgbẹ̀yìn àwọn gba ìyìnrere Ọlọ́run ha ti ?

18 "ó ṣe agbára káká ni a fi gba olódodo ,

níbo ni aláìwà-bí-Ọlọ́run àti ẹlẹ́ṣẹ̀ yóò yọjú ?"

19 Nítorí náà, jẹ́ àwọn ń jìyà gẹ́gẹ́ ìfẹ́ Ọlọ́run ni ṣíṣe rere, fi ọkàn wọn Ẹlẹ́dàá olóòtítọ́ lọ́wọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-