Publicidade

1 Timóteo 2

Àwọn ̀kọ́ lórí ìsìn

1 Nítorí náà mo gbà yín níyànjú ṣáájú ohun gbogbo, a máa bẹ̀bẹ̀, a máa gbàdúrà, a máa ṣìpẹ̀, àti a máa dúpẹ́ nítorí gbogbo ènìyàn. 2 Fún àwọn ọba, àti gbogbo àwọn ó ni ipò àṣẹ, a máa lo ayé wa àlàáfíà àti ìdákẹ́ jẹ́́ pẹ̀nínú gbogbo ìwà-bí-Ọlọ́run àti ìwà mímọ́. 3 Nítorí èyí dára, ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà níwájú Ọlọ́run Olùgbàlà wa; 4 ẹni ó fẹ́ gbogbo ènìyàn ìgbàlà wọ́n sínú ìmọ̀ òtítọ́. 5 Nítorí Ọlọ́run kan ń bẹ, onílàjà kan pẹ̀láàrín Ọlọ́run àti ènìyàn, àní Kristi Jesu ọkùnrin náà. 6 Ẹni ti ó fi ara rẹ̀ ṣe ìràpadà fún gbogbo ènìyàǹa fi fún ni àkókò yẹ. 7 Nítorí èyí a yàn mi ṣe oníwàásù, aposteli òtítọ́ ni èmi ń sọ, èmi ṣèké olùkọ́ àwọn aláìkọlà nínú ìgbàgbọ́ àti òtítọ́.

8 Mo fẹ́ àwọn ọkùnrin máa gbàdúrà níbi gbogbo, wọ́n máa gbé ọwọ́ mímọ́ sókè, àìbínú àti àìjiyàn. 9 Bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni àwọn obìnrin fi aṣọ ìwọ̀ntúnwọ̀nsì ṣe ara wọn ̀ṣọ́, ìwọ̀ntúnwọ̀nsì àti pẹ̀ìwà àìrékọjá; í ṣe pẹ̀irun dídì, tàbí wúrà, tàbí peali, tàbí aṣọ olówó iyebíye, 10 ṣe pẹ̀iṣẹ́ rere, èyí ó yẹ fún àwọn obìnrin jẹ́wọ́ wọ́n sin Ọlọ́run.

11 Jẹ́ obìnrin máa fi ìdákẹ́ jẹ́́ àti ìtẹríba gbogbo kọ́ ̀kọ́. 12 Ṣùgbọ́n èmi fi àṣẹ fún obìnrin láti máa kọ́ni, tàbí láti pàṣẹ lórí ọkùnrin, ṣe ó dákẹ́ jẹ́́. 13 Nítorí Adamu ni a kọ́ , lẹ́yìn náà, Efa. 14 Adamu kọ́ ni a tànjẹ, ṣùgbọ́n obìnrin náà ni a tàn ó di ẹlẹ́ṣẹ̀. 15 Ṣùgbọ́n a ó gbà àwọn obìnrin nípa ìbímọ wọn, wọ́n dúró nínú ìgbàgbọ́, ìfẹ́, àti ìwà mímọ́ pẹ̀ìwà àìrékọjá.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-