Publicidade

1 Timóteo 6

Àwọn ẹrú

1 Jẹ́ gbogbo àwọn i ṣe ẹrú lábẹ́ ìsìnrú máa ka àwọn olówó ó ni wọ́n yẹ ọlá gbogbo, a á sọ̀rọ̀-òdì orúkọ Ọlọ́run àti ̀kọ́ rẹ̀. 2 Àwọn ti ó ̀onígbàgbọ́, wọn ṣe ṣàìbọ̀wọ̀ fún wọn nítorí wọn jẹ́ arákùnrin; ṣùgbọ́n wọn túbọ̀ máa sìn wọ́n, nítorí àwọn í ṣe alábápín iṣẹ́ rere wọn jẹ́ onígbàgbọ́ àti olùfẹ́.

Ìfẹ́ owó

Nǹkan wọ̀nyí ni ó máa kọ́ ni, o máa fi gbani níyànjú. 3 ẹnikẹ́ni ń kọ́ni ̀kọ́ mìíràn, ti gba ̀rọ̀ ti ó kooro, ti Jesu Kristi Olúwa wa, àti ̀kọ́ ti ó ìwà-bí-Ọlọ́run mu, 4 Ó gbéraga, mọ̀ nǹkan kan, ṣe ìyànjú àti ìjà nípa ̀rọ̀ èyí ó ń ìlara, ìjà, ̀rọ̀ búburú , 5 àti ̀rọ̀ àríyànjiyàn àwọn ènìyàn ọlọ́kàn èérí ti òtítọ́ nínú wọn, tiwọn ṣe ̀èrè ni ìwà-bí-Ọlọ́run; yẹra lọ́dọ̀ irú àwọn wọ̀nyí.

6 Ṣùgbọ́n ìwà-bí-Ọlọ́run pẹ̀ìtẹ́lọ́rùn èrè ńlá ni. 7 Nítorí a ohun kan ayé, bẹ́̀ ni a mu ohunkóhun jáde lọ. 8 a ni oúnjẹ àti aṣọ, ìwọ̀nyí yẹ́ ó tẹ́ wa lọ́rùn. 9 Ṣùgbọ́n àwọn ń fẹ́ di ọlọ́rọ̀ a máa bọ́ sínú ìdánwò àti ìdẹ̀kùn, àti sínú òmùgọ̀ ìfẹ́kúfẹ̀́ púpọ̀ í pa ni lára, irú èyí ó máa ń ri ènìyàn sínú ìparun àti ègbé. 10 Nítorí ìfẹ́ owó ni gbòǹgbò ohun búburú gbogbo; èyí àwọn mìíràn ń lépa a wọn ṣìnà kúrò nínú ìgbàgbọ́, wọ́n fi ̀pọ̀ ìbànújẹ́ gún ara wọn lọ́kọ̀.

̀rọ̀ ìyànjú fún Timotiu

11 Ṣùgbọ́n ìwọ ènìyàn Ọlọ́run, fún nǹkan wọ̀nyí; ó máa lépa òdodo, ìwà-bí-Ọlọ́run, ìgbàgbọ́, ìfẹ́ sùúrù, ìwà tútù. 12 Máa ja ìjà rere ti ìgbàgbọ́, di ìyè àìnípẹ̀kun nínú èyí a , ti ìwọ ṣe ìjẹ́wọ́ rere níwájú ẹlẹ́rìí púpọ̀. 13 Mo pàṣẹ fún níwájú Ọlọ́run, ń sọ ohun gbogbo di ààyè, àti níwájú Jesu Kristi, ẹni ó jẹ́rìí níwájú Pọntiu Pilatu, 14 ìwọ pa àṣẹ wọ̀nyí mọ́ àìlábàwọ́n, àìlẹ́gàn, títí di ìfarahàn Olúwa wa Jesu Kristi. 15 Èyí ti yóò fihàn ìgbà tirẹ̀, Ẹni í ṣe Olùbùkún àti Alágbára kan ṣoṣo náà, ọba àwọn ọba, àti Olúwa àwọn Olúwa. 16 Ẹnìkan ṣoṣo ó jẹ àìkú, ń gbé inú ìmọ́lẹ̀ a súnmọ́, ẹni ènìyàn kan , a : ẹni ọlá àti agbára títí láé ń ṣe tirẹ̀. Àmín.

17 Kìlọ̀ fún àwọn ó lọ́rọ̀ ayé ìsinsin yìí wọn ma ṣe gbéraga, bẹ́̀ ni wọn ṣe gbẹ́kẹ̀̀rọ̀ àìdánilójú, ṣe Ọlọ́run alààyè, ń fi ohun gbogbo fún wa lọ́pọ̀lọ́pọ̀ láti ; 18 wọn máa ṣoore, wọn máa pọ̀ iṣẹ́ rere, wọn múra láti pín fún ni, wọn ni ̀ìbá kẹ́dùn; 19 wọn máa to ìṣúra ìpìlẹ̀ rere jọ fún ara wọn ìgbà ń bọ̀, wọn di ìyè tòótọ́ .

20 Timotiu, máa ṣọ ohun a fi ìkáwọ́ rẹ, kúrò nínú ̀rọ̀ asán àti ìjiyàn ohun a ń fi èké ni ìmọ̀; 21 èyí àwọn ẹlòmíràn jẹ́wọ́ rẹ̀ wọ́n ṣìnà ìgbàgbọ́.

oore-ọ̀fẹ́ pẹ̀rẹ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-