Publicidade

1 Tessalonicenses 1

1 1.1: 2Tẹ 1.1; 2Kọ 1.19; Ap 16.1; 17.1; Ro 1.7. Paulu, Sila àti Timotiu,

A kọ ́ ìjọ ó ìlú Tẹsalonika, àwọn ẹni ó jẹ́ ti Ọlọ́run Baba àti ti Olúwa Jesu Kristi:

ìbùkún àti àlàáfíà láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba àti Jesu Kristi ó jẹ́ tiyín.

Ọpẹ́ fún ìgbàgbọ́ àwọn ará Tẹsalonika

2 1.2: 2Tẹ 1.3; 2.13; Ro 1.9. Gbogbo ìgbà ni a máa ń fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run nítorí yín, a ń gbàdúrà fún un yín nígbà gbogbo pẹ̀. 3 1.3: 2Tẹ 1.11; 1.3; Ro 8.25; 15.4; Ga 1.4.A ń rántí yin ni àìsimi nígbà gbogbo níwájú Ọlọ́run àti Baba nípa iṣẹ́ ìgbàgbọ́ yín, iṣẹ́ ìfẹ́ yín àti ìdúró ṣinṣin ìrètí yín nínú Jesu Kristi Olúwa wa.

4 1.4: 2Tẹ 2.13; Ro 1.7; 2Pt 1.10. Àwa mọ̀ dájúdájú, ̀yin olùfẹ́ wa, Ọlọ́run ti yàn yín fẹ́ fún ara rẹ̀. 5 1.5: 2Tẹ 2.14; Ro 15.19.Nítorí , nígbà a ìyìnrere tọ̀ yín , ̀rọ̀ lásán ìtumọ̀ i yín, ṣe pẹ̀agbára, pẹ̀̀Mímọ́, pẹ̀ìdánilójú jinlẹ̀. ̀yin ti mọ irú ènìyàn àwa jẹ́ láàrín yín nítorí yín. 6 1.6: Kl 2.2; 1Tẹ 2.10; 1Kọ 4.16; 11.1; Ap 17.5-10; 13.52.bẹ́̀ ̀yin pàápàá di aláwòkọ́ṣe wa àti ti Olúwa, ìdí ni , gba ̀náà láti ọwọ́ ̀Mímọ́ pẹ̀ayọ̀ o tilẹ̀ jẹ́ , ó wàhálà àti ìbànújẹ́ fún yín. 7 1.7: Ro 15.26; Ap 18.12.bẹ́̀ ̀yin pàápàá fi di àpẹẹrẹ fún gbogbo àwọn onígbàgbọ́ agbègbè Makedonia àti Akaia. 8 1.8: 2Tẹ 3.1; Ro 1.8.̀rọ̀ Olúwa ti gbilẹ̀ níbi gbogbo láti ̀dọ̀ yín láti agbègbè Makedonia àti Akaia lọ, ìgbàgbọ́ yín nínú Ọlọ́run tàn káàkiri. Nítorí náà, a ni láti ṣẹ̀ṣẹ̀ ń sọ fún wọn nípa rẹ̀. 9 Ṣe ni wọ́n bẹ̀rẹ̀ i ròyìn fún wa ti gbà lálejò. Wọ́n ròyìn fún wa pẹ̀, ti yípadà kúrò nínú ìbọ̀rìṣà àti Ọlọ́run alààyè àti òtítọ́ nìkan ṣoṣo ni ń sìn, 10 1.10: Mt 3.7.àti láti fi ojú ṣọ́fún ìpadàbọ̀ Ọmọ rẹ̀ láti ̀run , ẹni ó dìde kúrò nínú òkú, Jesu, ẹni ó gbà lọ́wọ́ ìbínú ń bọ̀.

Veja também

1 Tessalonicenses
Ver todos os capítulos de 1 Tessalonicenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-