Publicidade

2 Coríntios 1

1 1.1: Ef 1.1; Kl 1.1; 2Kọ 1.19; Ap 16.1; 18.1. Paulu aposteli Jesu Kristi nípa ìfẹ́ Ọlọ́run, àti Timotiu arákùnrin ,

ìjọ Ọlọ́run ó Kọrinti pẹ̀gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́ ó gbogbo Akaia:

2 1.2: Ro 1.7. Oore-ọ̀fẹ́ yín àti àlàáfíà láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa, àti Jesu Kristi Olúwa.

Ọlọ́run gbogbo ìtùnú

3 1.3: Ef 1.3; 1Pt 1.3; Ro 15.5. Olùbùkún ni Ọlọ́run, àti Baba Jesu Kristi Olúwa wa, Baba ìyọ́, àti Ọlọ́run ìtùnú gbogbo. 4 1.4: 2Kọ 7.6-7,13.Ẹni ń nínú ni gbogbo ìdààmú wa, ki àwa pẹ̀máa tu àwọn ó nínú ìdààmú nínú, nípá ìtùnú náà ti a fi ń àwa fúnra wa nínú láti ̀dọ̀ Ọlọ́run . 5 Nítorí àwa ti pín nínú ìjìyà Kristi, gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ìtùnú wa púpọ̀ pẹ̀nípa Kristi. 6 Ṣùgbọ́n a ń pọ́n wa lójú, ó jẹ́ fún ìtùnú àti ìgbàlà yín; tàbí bi a ń nínú, ó jẹ́ fún ìtùnú yín ti ń ṣiṣẹ́ sùúrù láti yin irú ìfaradà ìyà kan náà ti àwa pẹ̀ń jẹ́. 7 Àti ìrètí wa nípa tiyín dúró ṣinṣin, àwa si mọ̀ , ̀yin ti jẹ alábápín nínú ìyà wa, bẹ́̀ ni ̀yin ń pín nínú ìtùnú náà pẹ̀.

8 Arákùnrin àti arábìnrin, àwa fẹ́ ̀yin jẹ́ òpè nípa wàhálà ó wa agbègbè Asia, ti a pọ́n wa lójú gidigidi rékọjá agbára ìfaradà wa, bẹ́̀ ìrètí tilẹ̀ fún ̀wa mọ́. 9 Nítòótọ́, nínú ọkàn wa a tilẹ̀ ìmọ̀lára a gba ìdálẹ́bi ikú, ṣùgbọ́n èyí farahàn láti wa gbẹ́kẹ̀ara wa ṣe Ọlọ́run ń òkú dìde. 10 Ẹni ó gbà kúrò nínú irú ikú ó tóbi bẹ́̀, yóò tún gbà ; òun àwa gbẹ́kẹ̀yóò máa gbà síbẹ̀síbẹ̀, 11 ̀yin pẹ̀ti ń fi àdúrà yín ràn lọ́wọ́. Àti ̀pọ̀ ènìyàn ni yóò dúpẹ́ nítorí wa fún oore-ọ̀fẹ́ ojúrere a gbà nípa ìdáhùn àdúrà ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn.

Paulu ìpinnu rẹ̀ padà

12 Nítorí èyí ìṣògo , ̀láti inú ọkàn wa pẹ̀si jẹ́rìí àwa ń gbé ìgbésí ayé ó ìtumọ̀ pàápàá jùlọ nínú ìbágbépọ̀ wa pẹ̀yín, nínú ìwà mímọ́ àti òtítọ́ láti ̀dọ̀ Ọlọ́run . í ṣe nípa ọgbọ́n ti ara ni àwa ń ṣe èyí ṣe nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run. 13 Nítorí àwa kọ̀ohun eyín àti ni mòye rẹ̀ yín. Mo tún ìrètí . 14 Gẹ́gẹ́ ̀yin pẹ̀ti ìmọ̀ nípa wa apá kan, bákan náà ni ó ìmọ̀ lẹ́kùnrẹ́rẹ́ ó fi yangàn, àwa pẹ̀yóò ṣe fi yín yangàn ọjọ́ Jesu Olúwa.

15 Nítorí mo ìdánilójú yìí , mo pinnu láti kọ́kọ́ bẹ̀ yín jẹ àǹfààní ìgbà méjì. 16 1.16: Ap 19.21.Mo pinnu láti bẹ̀ yín ìrìnàjò mi Makedonia àti láti tún bẹ̀ yín nígbà mo ń padà bọ̀ láti Makedonia àti ̀yin ó rán mi láti ̀dọ̀ yín ìrìnàjò mi Judea. 17 Nítorí náà nígbà èmi ń gbèrò bẹ́̀, èmi ha ṣiyèméjì ? Tàbí àwọn ohun mo pinnu, mo ha pinnu wọn gẹ́gẹ́ ti ará , ó jẹ́ "Bẹ́̀ , bẹ́̀ " àti "Bẹ́̀ kọ́, bẹ́̀ kọ́"?

18 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run jẹ́ olóòtítọ́, ̀rọ̀ wa fún yín í ṣe bẹ́̀ ni àti bẹ́̀ kọ́. 19 1.19: 1Tẹ 1.1; Ap 15.22.Nítorí Jesu Kristi, Ọmọ Ọlọ́run, ẹni a wàásù rẹ̀ láàrín yín nípasẹ̀ èmí àti Silfanu àti Timotiu, í ṣe bẹ́̀ ni bẹ́̀ kọ́, ṣùgbọ́n nínú rẹ̀ ni bẹ́̀ . 20 1.20: 1Kọ 14.16; If 3.14.Nítorí gbogbo ìlérí Ọlọ́run bẹ́̀ ni nínú Kristi. Nítorí ìdí èyí a ṣe ń "Àmín" nípasẹ̀ rẹ̀ ògo Ọlọ́run. 21 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, Ọlọ́run ni ó fi ẹsẹ̀ wa múlẹ̀ pẹ̀yín nínú Kristi, Òun ni ó ti fi àmì òróró yàn , 22 ó fi èdìdì rẹ̀ pẹ̀, ó fi ̀rẹ́ wa ọkàn gẹ́gẹ́ ̀ìdánilójú ohun ó ń bọ̀.

23 Mo pe Ọlọ́run ṣe ẹlẹ́rìí ọkàn mi nítorí àti yín èmi ṣe padà Kọrinti. 24 í ṣe nítorí àwa jẹ gàba lórí ìgbàgbọ́ yín, ṣùgbọ́n àwa ń ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀yín fún ayọ̀ yín nítorí nípa ìgbàgbọ́ ni ̀yin dúró ṣinṣin.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-