Publicidade

2 Coríntios 12

Ìṣípayá Paulu àti ̀gún n bẹ lára rẹ̀

1 Èmi ṣàì ṣògo tilẹ̀ ṣe àǹfààní, nítorí èmi ó sọ nípa ìran àti ìṣípáyà ti Olúwa fihàn . 2 Èmi mọ ọkùnrin kan nínú Kristi ọdún mẹ́rìnlá sẹ́yìn, yálà nínú ara ni, èmi mọ̀; tàbí kúrò nínú ara, èmi mọ̀; Ọlọ́run mọ̀: a gbé irú ẹni náà lọ ̀run kẹta. 3 Bẹ́̀ ni èmi mọ irú ọkùnrin bẹ́̀, yálà ara ni, tàbí kúrò nínú ara ni, èmi mọ̀: Ọlọ́run mọ̀. 4 a gbé e lọ sókè Paradise, ó gbọ́ ̀rọ̀ a sọ, tọ́ fún ènìyàn láti máa sọ. 5 Nípa irú ẹni bẹ́̀ ni èmi ó máa ṣògo, ṣùgbọ́n nípa ti èmi tìkára mi èmi yóò ṣògo, ṣe nínú àìlera mi. 6 Nítorí bi èmi tilẹ̀ ń fẹ́ máa ṣògo, èmi yóò jẹ́ òmùgọ̀; nítorí èmi yóò sọ òtítọ́: ṣùgbọ́n mo kọ̀, ẹnikẹ́ni máa à fi ju ohun ó èmi jẹ́ lọ, tàbí ju èyí ó gbọ́ lẹ́nu mi, 7 àti nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ìṣípayá, èmi ba à gbé ara mi ga rékọjá, a ti fi ̀gún kan mi lára, ìránṣẹ́ Satani láti pọ́n mi lójú, èmi a gbéraga rékọjá. 8 Nítorí nǹkan yìí ni mo ṣe bẹ Olúwa nígbà mẹ́ta , ó e kúrò lára mi. 9 Òun fún mi , "Oore-ọ̀fẹ́ mi fún , nítorí a sọ agbára mi di pípé nínú àìlera." Nítorí náà tayọ̀tayọ̀ ni èmi ó kúkú máa fi ṣògo nínú àìlera mi, agbára Kristi máa gbé inú mi. 10 Nítorí náà èmi inú dídùn nínú àìlera gbogbo, nínú ̀gàn gbogbo, nínú àìní gbogbo, nínú inúnibíni gbogbo, nínú wàhálà gbogbo nítorí Kristi. Nítorí nígbà mo jẹ́ aláìlera, nígbà náà ni mo di alágbára.

Àníyàn Paulu nípa àwọn ará Kọrinti

11 Mo di òmùgọ̀ nípa ṣíṣògo; ̀yin ó fi ipá mi ṣe é, nítorí ó tọ́ yìn , nítorí èmi rẹ̀yìn lóhunkóhun àwọn àgbà aposteli èmi tilẹ̀ jámọ́ nǹkan kan. 12 Ohun kan ó ṣe àmì aposteli, iṣẹ́ ìyanu àti iṣẹ́ agbára ni wọ́n ṣe àárín yín pẹ̀sùúrù ga. 13 Nítorí nínú kín ni ohun ̀yin ṣe rẹ̀yìn ìjọ mìíràn, ṣe ti èmi fúnra mi jẹ́ oníyọnu fún yín? dárí àṣìṣe yìí .

14 Kíyèsi i, ìgbà kẹta yìí ni mo múra tan láti tọ̀ yín , èmi yóò jẹ́ oníyọnu fún yín nítorí èmi nǹkan yín, ṣe ̀yin fúnra yín; nítorí tọ́ fún àwọn ọmọ láti máa to ìṣúra jọ fún àwọn òbí wọn, ṣe àwọn òbí fún àwọn ọmọ wọn. 15 Èmi ó fi ayọ̀ ohun gbogbo mo , èmi ó ara mi fún ọkàn yín nítòótọ́; mo fẹ́ yín lọ́pọ̀lọ́pọ̀, ó ha tọ́ ̀yin ó fẹ́ràn mi díẹ̀ ? 16 Ṣùgbọ́n ó dára bẹ́̀ èmi dẹ́rùbà yín, ṣùgbọ́n ọlọ́gbọ́n ènìyàn, èmi ń fi ọwọ́ ̀rọ̀ yín. 17 Èmi ha rẹ́ yín jẹ nípa ẹnikẹ́ni nínú àwọn mo rán yín bi? 18 Mo bẹ Titu, mo rán arákùnrin kan pẹ̀rẹ̀; Titu ha rẹ́ yín jẹ ? Nípa ̀kan náà kọ́ ni àwa rìn ? ̀kan náà kọ́ ni àwa tọ̀ ?

19 ̀yin ha àwa ń sọ nǹkan wọ̀nyí láti gbèjà ara wa níwájú yín ? iwájú Ọlọ́run ni àwa ń sọ̀rọ̀ nínú Kristi; ṣùgbọ́n àwa ń ṣe ohun gbogbo, olùfẹ́ ̀wọ́n, láti gbé yín ni. 20 Nítorí ̀ń , nígbà mo , èmi yóò yín gẹ́gẹ́ irú èyí mo fẹ́, àti ̀yin yóò mi gẹ́gẹ́ irú èyí ̀yin fẹ́: ìjà, owú jíjẹ, ìbínú, ìpinyà, ìṣọ̀rọ̀-ẹni-lẹ́yìn, òfófó, ìgbéraga, ìrúkèrúdò, ba à . 21 Àti nígbà mo padà , Ọlọ́run à rẹ̀ sílẹ̀ lójú yín, àti èmi ba à sọkún nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ó ṣẹ̀ náà ronúpìwàdà ̀ṣẹ̀ ìwà èérí, àgbèrè, àti wọ̀bìà wọ́n ti .

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-