Publicidade

2 Coríntios 13

Àwọn ìkìlọ̀ ìkẹyìn

1 Èyí ni ó ìgbà kẹta èmi ń tọ̀ yín . ẹnu ẹlẹ́rìí méjì tàbí mẹ́ta ni a ó fi ìdí ̀rọ̀ gbogbo múlẹ̀. 2 Mo ti sọ fún yín ṣáájú, mo ń sọ fún yín tẹ́lẹ̀, ẹni mo pẹ̀yín nígbà kejì, àti èmi ti lọ́dọ̀ yín ìsinsin yìí, mo kọ̀àwọn ó ti ṣẹ̀ náà, àti gbogbo àwọn ẹlòmíràn, mo tún padà , èmi yóò wọn . 3 Níwọ́n ̀yin ń àmì Kristi ti ń sọ̀rọ̀ nínú mi, ẹni í ṣe àìlera yin, ṣùgbọ́n ó jẹ́ agbára nínú yín. 4 Nítorí a kàn án mọ́ àgbélébùú nípa àìlera, ṣùgbọ́n òun láààyè nípa agbára Ọlọ́run. Nítorí àwa pẹ̀jásí aláìlera nínú rẹ̀, ṣùgbọ́n àwa yóò láààyè pẹ̀rẹ̀ nípa agbára Ọlọ́run yín.

5 máa wádìí ara yín, ̀yin nínú ìgbàgbọ́; máa dán ara yín . Tàbí ̀yin fúnra yín mọ ara yín Jesu Kristi nínú yín? Àfi ̀yin jẹ́ àwọn a tanù. 6 Ṣùgbọ́n mo ìgbẹ́kẹ̀̀yin yóò mọ̀ , àwa í ṣe àwọn a tanù. 7 Ǹjẹ́ àwa ń gbàdúrà Ọlọ́run, í ṣe nítorí àwa farahàn àwọn ti ó tayọ̀, ṣùgbọ́n ̀yin máa ṣe èyí ó dára àwa tilẹ̀ dàbí àwọn a tanù. 8 Nítorí àwa ṣe ohun kan lòdì òtítọ́, ṣe fún òtítọ́. 9 Nítorí àwa ń yọ̀, nígbà ti àwa jẹ́ aláìlera, ̀yin jẹ́ alágbára; èyí ni àwa ń gbàdúrà fún pẹ̀, àní pípé yín. 10 Ìdí nìyí ti mo ṣe kọ̀àwọn nǹkan wọ̀nyí nígbà èmi lọ́dọ̀ yín, nígbà mo èmi ba à lo ìkanra lílo àṣẹ, gẹ́gẹ́ àṣẹ Olúwa ti fi fún , láti ìdàgbàsókè, í ṣe láti yín ṣubú.

Ìkíni ìkẹyìn

11 àkótán, ará ó gbòóṣe, ṣe àtúnṣe ̀yín, tújúká, jẹ́ onínú kan, máa àlàáfíà, Ọlọ́run ìfẹ́ àti ti àlàáfíà yóò pẹ̀yín.

12 fi ìfẹnukonu mímọ́ ara yín.

13 Gbogbo àwọn ènìyàn Ọlọ́run níbi i yín.

14 Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa, àti ìfẹ́ Ọlọ́run, àti ìdàpọ̀ ti Èmí Mímọ́, ó pẹ̀gbogbo yín.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-