Publicidade

2 Coríntios 3

1 3.1: Ap 18.27; Ro 16.1; 1Kọ 16.3. Àwa ha tún bẹ̀rẹ̀ láti máa yín ara ? Tàbí àwa ha ń fẹ́ ìwé ìyìn sọ́dọ̀ yín, tàbí láti ̀dọ̀ yín gẹ́gẹ́ ẹlòmíràn ń ṣe? 2 ̀yin fúnra yín ni ìwé ìyìn wa, a ti kọ yín ọkàn, ti gbogbo ènìyàn mọ̀, wọ́n ń . 3 3.3: Ek 24.12; 31.18; 32.15-16; Jr 31.33.̀yin ń fihàn ìwé a gbà sílẹ̀ láti ̀dọ̀ Kristi ni yín, í ṣe èyí a fi jẹ́kọ, sẹ ̀Ọlọ́run alààyè, í ṣe nínú wàláà òkúta ṣe nínú wàláà ọkàn ẹran.

4 Irú ìgbẹ́kẹ̀yìí ni àwa nípasẹ̀ Kristi sọ́dọ̀ Ọlọ́run, 5 í ṣe àwa fún ara wa láti ṣírò ohunkóhun ẹni láti ̀dọ̀ àwa tìkára wa; ṣùgbọ́n láti ̀dọ̀ Ọlọ́run tító , 6 Ẹni ó wa yẹ ìránṣẹ́ májẹ̀tuntun; í ṣe ti ìwé àkọsílẹ̀ ṣùgbọ́n ti ̀, nítorí ìwé a máa pa ni, ṣùgbọ́n ̀a máa sọ di ààyè.

Ògo nínú májẹ̀tuntun

7 3.7: Ek 34.29-35. Ṣùgbọ́n iṣẹ́ ìránṣẹ́ ikú, a kọ a ti gbẹ́ ara òkúta jẹ́ ológo bẹ́̀ àwọn ọmọ Israẹli tẹjúmọ́ wíwo ojú Mose nítorí ògo ojú rẹ̀ (ògo ti ń kọjá lọ); 8 yóò ha ti iṣẹ́ ìránṣẹ́ ti ̀yóò kúkú jẹ́ ògo ? 9 Nítorí bi iṣẹ́ ìránṣẹ́ ìdálẹ́bi jẹ́ ológo, mélòó mélòó ni iṣẹ́ ìránṣẹ́ òdodo yóò tayọ ú ògo. 10 Nítorí, èyí a ṣe lógo , lógo mọ́ báyìí, nítorí ògo ó tayọ. 11 Nítorí èyí ti ń kọjá lọ lógo, mélòó mélòó ni èyí ó dúró yóò ògo!

12 Ǹjẹ́ nítorí náà a irú ìrètí èyí, àwa ń fi ìgboyà púpọ̀ sọ̀rọ̀. 13 í í ṣe Mose, ẹni ó fi ìbòjú bo ojú rẹ̀, ki àwọn ọmọ Israẹli ba à tẹjúmọ́ wíwo òpin èyí ń kọjá lọ. 14 Ṣùgbọ́n ojú inú wọn fọ́; nítorí títí fi di òní olónìí nípa kíka májẹ̀láéláé, ìbòjú kan náà ṣì láìká kúrò; nítorí nínú Kristi ni a ìbòjú náà kúrò. 15 Ṣùgbọ́n títí di òní olónìí, nígbàkígbà ti a ń ka Mose, ìbòjú náà ń bẹ lọ́kàn wọn. 16 Ṣùgbọ́n nígbà ti òun yípadà Olúwa, a ó ìbòjú náà kúrò. 17 3.17: Isa 61.1-2.Ǹjẹ́ Olúwa ni ̀náà: níbi ̀Olúwa , níbẹ̀ ni òmìnira gbé . 18 Ṣùgbọ́n gbogbo wa ń wo ògo Olúwa láìsí ìbòjú ẹni nínú àwòjìji, a ń pa wa àwòrán kan náà láti ògo ògo, àní láti ̀dọ̀ Olúwa í ṣe ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-