Publicidade

2 Coríntios 5

Ibùgbé wa ọrun

1 Nítorí àwa mọ̀ , bi ilé àgọ́ wa ti ayé ba , àwa ilé kan láti ̀dọ̀ Ọlọ́run, ilé a fi ọwọ́ kọ́, ti ayérayé nínú àwọn ̀run. 2 Nítorí nítòótọ́ àwa ń kérora nínú èyí, àwa ń fẹ́ gidigidi láti fi ilé wa ti ̀run wọ̀ . 3 ó ṣe a ti fi wọ̀ , a yóò wa ìhòhò. 4 Nítorí àwa a ń bẹ nínú àgọ́ yìí ń kérora nítòótọ́, í ṣe nítorí àwa fẹ́ jẹ́ aláìwọṣọ, ṣùgbọ́n a ó wọ̀ aṣọ i, ìyè ba à gbé ara kíkú . 5 Ǹjẹ́ ẹni ó ti pèsè wa fún nǹkan yìí ni Ọlọ́run, ẹni o ti fi ̀fún wa pẹ̀ni ̀ìdánilójú ohun ń bọ̀.

6 Nítorí náà àwa ìgboyà nígbà gbogbo, àwa mọ̀ , nígbà àwa ń bẹ ilé nínú ara, àwa lọ́dọ̀ Olúwa. 7 Àwa ń gbé nípa ìgbàgbọ́, í ṣe nípa . 8 Mo , àwa ìgboyà, àwa ń fẹ́ a kúkú ti inú ara kúrò, a ilé lọ́dọ̀ Olúwa. 9 Nítorí náà àwa ń ṣakitiyan, , àwa ilé tàbí a , àwa jẹ́ ẹni ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ rẹ̀. 10 Nítorí gbogbo wa ni ó gbọdọ̀ fi ara hàn níwájú ìtẹ́ ìdájọ́ Kristi; olúkúlùkù gbà èyí ó ṣe gẹ́gẹ́ èyí ó tọ́ i nígbà ó nínú ara ìbá à ṣe rere tàbí búburú.

Iṣẹ́ ìránṣẹ́ ìlàjà a sọ́tọ̀

11 Nítorí náà àwa ti mọ ̀Olúwa, àwa ń ènìyàn lọ́kàn padà; ṣùgbọ́n a ń fi hàn fún Ọlọ́run; mo gbàgbọ́ , a ti hàn ọkàn yín pẹ̀. 12 Nítorí àwa máa tún yin ara i yín mọ́, ṣùgbọ́n àwa fi ààyè fún yín láti máa ṣògo nítorí wa, ohun ̀yin yóò fi wọn lóhùn, àwọn ti ń ṣògo lóde ara í ṣe ọkàn. 13 Nítorí náà àwa ń sínwín, fún Ọlọ́run ni tàbí iyè ṣí pépé, fún yín ni. 14 Nítorí ìfẹ́ Kristi ń rọ̀ , nítorí àwa mọ̀ báyìí , ẹnìkan fún gbogbo ènìyàn, ǹjẹ́ nígbà náà, gbogbo wọ́n ni ó ti . 15 Ó ti fún gbogbo wọn, àwọn ó láààyè ṣe láààyè fún ara wọn mọ́, ṣe fún ẹni ó nítorí wọn, ó ti jíǹde.

16 Nítorí náà láti ìsinsin yìí lọ, àwa mọ ẹnìkan nípa ti ara mọ́; àwa tilẹ̀ ti mọ Kristi nípa ti ara, ṣùgbọ́n nísinsin yìí àwa mọ̀ ́n bẹ́̀ mọ́. 17 Nítorí náà ẹnìkan nínú Kristi, ó di ̀tuntun: ohun àtijọ́ ti kọjá lọ; kíyèsi i, ohun tuntun ti . 18 Ohun gbogbo ti ̀dọ̀ Ọlọ́run , ẹni ó tipasẹ̀ Jesu Kristi wa làjà sọ́dọ̀ ara rẹ̀, ó ti fi iṣẹ́ ìránṣẹ́ ìlàjà fún wa. 19 Èyí ni , Ọlọ́run nínú Kristi, ó ń aráyé làjà sọ́dọ̀ ara rẹ̀, ka ìrékọjá wọn wọn lọ́rùn; ó ti fi ̀rọ̀ ìlàjà wa lọ́wọ́. 20 Nítorí náà àwa ni ikọ̀ fún Kristi, ẹni Ọlọ́run ń ti ̀dọ̀ wa ṣìpẹ̀ fún yín: àwa ń bẹ̀ yín ipò Kristi, "Ọlọ́run làjà." 21 Nítorí ó fi í ṣe ̀ṣẹ̀ nítorí wa, ẹni mọ ̀ṣẹ̀kẹ́ṣẹ̀ , àwa di òdodo Ọlọ́run nínú rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-