Publicidade

2 Coríntios 8

̀rọ̀ ìyànjú lórí ìfifúnni

1 Pẹ̀lúpẹ̀, ará, àwa ń sọ fún yín ti oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run a fífún àwọn ìjọ Makedonia. 2 ó ti jẹ́ a dán wọn nípa ìpọ́njú, ̀pọ̀lọpọ̀ ayọ̀ àti àìlódiwọ̀n àìní wọn ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ nínú ̀rọ̀ ìlawọ́ wọn. 3 Nítorí mo jẹ́rìí gẹ́gẹ́ agbára wọn, àní ju agbára wọn, wọ́n ṣe é láti ìfẹ́ inú ara wọn. 4 Wọ́n ń fi ̀bẹ̀ púpọ̀ rọ̀ ti ̀bùn àtinúwá yìí, láti ba à ìpín nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ fún àwọn ènìyàn mímọ́. 5 Àti èyí, í ṣe àwa , ṣùgbọ́n wọ́n tètè kọ́ fi àwọn fúnra wọn fún Olúwa, àti fún , nípa ìfẹ́ Ọlọ́run. 6 bẹ́̀ àwa fi gba Titu níyànjú , ó bẹ̀rẹ̀ náà, bẹ́̀ ni ó parí ̀bùn ̀fẹ́ yìí nínú yín pẹ̀. 7 Ṣùgbọ́n ̀yin ti pọ̀ lóhùn gbogbo, ìgbàgbọ́, àti ̀rọ̀ àti ìmọ̀, àti nínú iṣẹ́ ìyìnrere gbogbo, àti ìfẹ́ yín wa, i ̀yin pọ̀ i nínú ̀bùn ̀fẹ́ yìí pẹ̀.

8 í ṣe nípa àṣẹ ni mo fi ń sọ ́, ṣùgbọ́n a ìdí òtítọ́ ìfẹ́ yín pẹ̀, nípa iṣẹ́ ìyìnrere ẹlòmíràn. 9 Nítorí ̀yin mọ oore-ọ̀fẹ́ Olúwa wa Jesu Kristi, òun ti jẹ́ ọlọ́rọ̀ ṣùgbọ́n nítorí yín ó di tálákà a sọ yín di ọlọ́rọ̀ nípa àìní rẹ̀.

10 Àti nínú èyí ni mo fi ìmọ̀ràn mi fún yín, nítorí èyí ṣe àǹfààní fún yín, ̀yin ó kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ níwọ̀n ọdún ó kọjá, í ṣe láti ṣe nǹkan, ṣùgbọ́n láti fẹ́ pẹ̀. 11 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, parí ṣíṣe iṣẹ́ náà pẹ̀; ó ba à ṣe , ìpinnu fún ṣíṣe ti , bẹ́̀ ni ìparí láti inú agbára yín. 12 Nítorí ìpinnu ṣáájú, ó jásí ìtẹ́wọ́gbà gẹ́gẹ́ ohun ènìyàn , í ṣe gẹ́gẹ́ ohun .

13 Nítorí èmi fẹ́ àwọn ẹlòmíràn ìrọ̀rùn, ó jẹ́ ìpọ́njú fún yín, ṣùgbọ́n nípa mímú dọ́gba. 14 àkókò yìí, àníṣẹ́yín ṣe déédé àìní wọn, àníṣẹ́tiwọn pẹ̀ba à ṣe déédé àìní yín, ìmúdọ́gba ba à . 15 Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ , "Ẹni ó púpọ̀ púpọ̀ , bẹ́̀ ni ẹni ó ìwọ̀nba kéré ."

A rán Titu Kọrinti

16 Ṣùgbọ́n ọpẹ́ fún Ọlọ́run ẹni ó fi ìtara àníyàn kan náà yìí ọkàn Titu fún yín. 17 Nítorí í ṣe òun gba ̀rọ̀ ìyànjú wa nìkan ni; ṣùgbọ́n òun ti ìtara púpọ̀, òun tìkára rẹ̀ tọ̀ yín , fúnra rẹ̀. 18 Àwa ti rán arákùnrin náà pẹ̀rẹ̀, ìyìn ẹni ó nínú ìyìnrere yíká gbogbo ìjọ. 19 í í ṣe bẹ́̀ nìkan, ṣùgbọ́n ẹni a yàn pẹ̀láti ̀dọ̀ ìjọ láti máa wa rìn kiri nínú ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ yìí, àwa ń ṣe ìránṣẹ́ rẹ̀ fún ògo Olúwa àti ìmúra ìtara wa. 20 Àwa ń yẹra fún èyí, ẹnikẹ́ni ba à wa ti ̀bùn àtinúwá yìí àwa pín. 21 Àwa ń gbèrò ohun rere, í ṣe níwájú Olúwa nìkan, ṣùgbọ́n níwájú ènìyàn pẹ̀.

22 Àwa ti rán arákùnrin wa pẹ̀wọn, ẹni àwa dájú nígbà púpọ̀ ó ìtara nínú ohun púpọ̀, ṣùgbọ́n ìsinsin yìí ni ìtara rẹ̀ túbọ̀ pọ̀ i nípa ìfọkàntán ńlá ó yín. 23 ẹnikẹ́ni béèrè ẹni Titu jẹ́, ẹlẹgbẹ́ àti olùbáṣiṣẹ́ mi ni, nítorí yín; tàbí ti àwọn arákùnrin wa ni ẹnikẹ́ni ń béèrè, ìránṣẹ́ ìjọ ni wọ́n jẹ́, àti ògo Kristi. 24 Nítorí náà fi ̀ìfẹ́ yín hàn wọ́n níwájú ìjọ, àti ìṣògo wa nítorí yín.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-