Publicidade

2 Pedro 1

1 Simoni Peteru, ìránṣẹ́ àti aposteli Jesu Kristi,

àwọn ó gba irú iyebíye ìgbàgbọ́ kan náà pẹ̀nínú òdodo Ọlọ́run wa àti ti Jesu Kristi Olùgbàlà:

2 oore-ọ̀fẹ́ àti àlàáfíà máa i fún yín nínú ìmọ̀ Ọlọ́run àti ti Jesu Olúwa wa.

Mímú ìpè àti yíyàn ẹni dájú

3 agbára rẹ̀ Ọlọ́run ti fún wa ohun gbogbo a nílò fún ṣe ti ìyè àti ti ìwà-bí-Ọlọ́run, nípa ìmọ̀ ẹni ó nípa Ògo àti ìṣeun rẹ̀. 4 Nípa èyí ó fi àwọn ìlérí rẹ̀ ó tóbi púpọ̀ ó ṣe iyebíye fún wa: nípa ìwọ̀nyí ni ̀yin di alábápín nínú àbùdá ti Ọlọ́run, nígbà ̀yin ti yọ kúrò nínú ìbàjẹ́ ó ń bẹ nínú ayé nípa ìfẹ́kúfẹ̀́.

5 Àti nítorí ìdí èyí, máa ṣe àìsimi gbogbo, fi ìwà rere kún ìgbàgbọ́, àti ìmọ̀ kún ìwà rere; 6 àti àìrékọjá kún ìmọ̀; àti sùúrù kún àìrékọjá; àti ìwà-bí-Ọlọ́run kún sùúrù. 7 Àti ìfẹ́ ọmọnìkejì kún ìwà-bí-Ọlọ́run; àti ìfẹ́ni kún ìfẹ́ ọmọnìkejì. 8 Nítorí ̀yin nǹkan wọ̀nyí wọ́n pọ̀, wọn yóò jẹ́ ṣe ̀lẹ tàbí aláìléso nínú ìmọ̀ Olúwa wa Jesu Kristi. 9 Ṣùgbọ́n ẹni ó ṣe aláìní nǹkan wọ̀nyí, ríran òkèèrè, ó fọjú, ó ti gbàgbé a ti wẹ òun kúrò nínú ̀ṣẹ̀ rẹ̀ àtijọ́.

10 Nítorí náà, ará túbọ̀ máa ṣe àìsimi láti sọ ìpè àti yíyàn yín di dájúdájú, nítorí ̀yin ń ṣe nǹkan wọ̀nyí, ̀yin yóò ṣubú. 11 Nítorí báyìí ni a ó pèsè fún yín lọ́pọ̀lọ́pọ̀ láti wọ ìjọba àìnípẹ̀kun ti Olúwa àti Olùgbàlà wa Jesu Kristi.

Àsọtẹ́lẹ̀ ti ọrọ̀ Ọlọ́run

12 Nítorí náà, èmi ó máa rán yin létí àwọn nǹkan wọ̀nyí nígbà gbogbo, ó tilẹ̀ jẹ́ ̀yin ti mọ̀ wọ́n, ẹsẹ̀ yín múlẹ̀ nínú òtítọ́ báyìí. 13 Èmi ó tọ́ láti máa wọn ìrántí yín, níwọ̀n ìgbà èmí ba ń bẹ nínú àgọ́ ara yìí. 14 èmi ti mọ̀ , bíbọ́ àgọ́ ara mi yìí sílẹ̀ dẹ̀dẹ̀, àní, Olúwa wa Jesu Kristi ti fihàn . 15 Èmi ó máa ṣaápọn pẹ̀, ̀yin máa rántí nǹkan wọ̀nyí nígbà gbogbo lẹ́yìn ikú mi.

16 Nítorí í ṣe ẹni ó ń tọ ìtàn asán lẹ́yìn a fi ọgbọ́nkọ́gbọ́n sílẹ̀, nígbà àwa sọ fún yín ti agbára àti wíwá Jesu Kristi Olúwa, ṣùgbọ́n ẹlẹ́rìí ọláńlá rẹ̀ ni àwa jẹ́. 17 Nítorí Ó gba ọlá àti ògo láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba, nígbà irú ohùn yìí fọ̀ i láti inú ògo ńlá náà , "Èyí ni àyànfẹ́ ọmọ mi, ẹni inú mi dùn gidigidi." 18 Àwa pẹ̀gbọ́ ohun yìí ó ti ̀run nígbà àwa pẹ̀rẹ̀ orí òkè mímọ́ náà.

19 Àwa ìfẹsẹ̀múlẹ̀ ̀rọ̀ àwọn wòlíì dunjúdunjú i, èyí ó yẹ kíyèsi gẹ́gẹ́ fìtílà ń mọ́lẹ̀ níbi òkùnkùn gbé , títí ilẹ̀ yóò fi mọ́, ìràwọ̀ òwúrọ̀ yóò yọ lọ́kàn yín. 20 Ju gbogbo rẹ̀ lọ, òye yìí àsọtẹ́lẹ̀ ìwé mímọ́ kankan ó wáyé nípa ìtumọ̀ wòlíì fún rara rẹ̀. 21 Nítorí àsọtẹ́lẹ̀ kan ti ipá ìfẹ́ ènìyàn ; ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn ń sọ̀rọ̀ láti ̀dọ̀ Ọlọ́run a ti ń darí wọn láti ọwọ́ ̀Mímọ́ .

Veja também

Publicidade
2 Pedro
Ver todos os capítulos de 2 Pedro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-