Publicidade

2 Pedro 2

Àwọn olùkọ́ni èké àti ìparun wọn

1 2.1-18: Jd 4-16. Ṣùgbọ́n àwọn wòlíì èké láàrín àwọn ènìyàn náà pẹ̀, gẹ́gẹ́ àwọn olùkọ́ni èké yóò ti láàrín yín. Wọn yóò yọ́ kẹ́lẹ́ ̀kọ́ òdì àti ègbé tọ̀ yín wa, àní yóò sẹ́ Olúwa ó wọ́n padà, wọ́n ó ìparun ti o yára kánkán sórí ara wọn. 2 ̀pọ̀lọpọ̀ ni yóò si máa tẹ̀̀ìtìjú wọn, wọn yóò ̀òtítọ́ di ìsọ̀rọ̀-òdì . 3 Nínú ìwà wọ̀bìà wọn, àwọn ẹlẹ́kọ̀́ òdì wọ̀nyí yóò máa rẹ́ yín jẹ nípa ìtàn asán. Ìdájọ́ ẹni falẹ̀ láti ìgbà yìí àti ìparun wọn tòògbé.

4 Nítorí bi Ọlọ́run àwọn angẹli si nígbà wọn ṣẹ̀, ṣùgbọ́n ti ó sọ wọ́n ìsàlẹ̀ ̀run àpáàdì ó fi wọ́n sínú ̀gbun òkùnkùn biribiri nínú ìfipamọ́ títí ìdájọ́. 5 2.5: Gẹ 8.18; 6.6-8.òun si ayé ìgbàanì , nígbà ó ìkún omi sórí ayé àwọn aláìwà-bí-Ọlọ́run, ṣùgbọ́n ó pa Noa mọ́, oníwàásù òdodo, pẹ̀àwọn ọmọ méje mìíràn. 6 2.6: Gẹ 19.24.ó sọ àwọn ìlú Sodomu àti Gomorra di eérú, nígbà ó fi ìparun pátápátá wọn lẹ́bi, ó fi wọ́n ṣe àpẹẹrẹ fún àwọn yóò jẹ́ aláìwà-bí-Ọlọ́run. 7 2.7: Gẹ 19.16,29.ó yọ Lọti olóòtítọ́ ènìyàn, ẹni ìwà ̀gbin àwọn ènìyàn láìlófin nínú jẹ́; 8 (nítorí ọkùnrin olóòtítọ́ náà ó ti ń gbé àárín wọn, ó ń , ó ń gbọ́, lójoojúmọ́ ni ìwà búburú wọn ń ọkàn òtítọ́ rẹ̀ jẹ́). 9 ó bẹ́̀, Olúwa mọ a ń yọ àwọn ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run kúrò nínú ìdánwò àti a ti ń pa àwọn aláìṣòótọ́ mo fún ọjọ́ ìdájọ́ nígbà wọn yóò tẹ̀síwájú nínú ìjìyà ̀ṣẹ̀ wọn. 10 Ṣùgbọ́n pàápàá àwọn ó ń tọ ẹran-ara lẹ́yìn nínú ìfẹ́kúfẹ̀́ ìwà èérí, wọ́n ń gan àwọn ìjòyè.

Àwọn ̀dájú àti agbéraga, wọn bẹ̀láti sọ̀rọ̀ ̀gàn àwọn ẹni ògo. 11 Bẹ́̀ ni àwọn angẹli wọ́n ti pọ̀ agbára àti ipá o , wọn wọ́n lẹ́jọ́ ̀gàn níwájú Olúwa. 12 Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí, ẹranko igbó èrò, ẹranko á a láti máa pa, wọ́n ń sọ̀rọ̀ ̀gàn nínú ̀rọ̀ wọn, a ó pa wọn run pátápátá nínú ìbàjẹ́ ara wọn.

13 Wọn yóò gba ibi padà ibi wọ́n ti ṣe. Òye ìgbafẹ́ wọ́n láti máa jẹ adùn ayé. Wọ́n jẹ́ àbàwọ́n àti àbùkù, wọ́n ń jayé nínú ìfẹ́kúfẹ̀́ wọn nígbà wọ́n ń jẹ àsè pẹ̀yín. 14 Ojú wọn kún fún panṣágà, wọn dẹ́kun ̀ṣẹ̀ dídá; wọ́n ń tan àwọn ọkàn fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ jẹ; àwọn wọ́n ọkàn ó ti yege nínú wọ̀bìà, ọmọ ègún ni wọ́n. 15 2.15: Nu 22.5,7.Wọ́n kọ ̀ó tọ́ sílẹ̀, wọ́n ṣáko lọ, wọ́n tẹ̀̀Balaamu ọmọ Beori, ẹni fẹ́ràn èrè àìṣòdodo. 16 2.16: Nu 22.21,23,28,30-31.Ṣùgbọ́n a a nítorí ìrékọjá rẹ̀, odi kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ fi ohùn ènìyàn sọ̀rọ̀, ó fi òpin ìṣiwèrè wòlíì náà.

17 Àwọn wọ̀nyí ni kànga omi, ìkùùkuu ̀fúùfù ń gbá kiri; àwọn ẹni a pa òkùnkùn biribiri mọ́ títí láé. 18 Nítorí ìgbà wọ́n ń sọ̀rọ̀ ìhàlẹ̀ asán, nínú ìfẹ́kúfẹ̀́ ara, wọn a máa tan àwọn wọ́n fẹ́rẹ̀ ì bọ́ tán kúrò lọ́wọ́ àwọn wọ́n nínú ìṣìnà. 19 Wọn a máa ṣe ìlérí òmìnira fún wọn, nígbà àwọn pàápàá jẹ́ ẹrú ìdíbàjẹ́; nítorí ènìyàn di ẹrú ohunkóhun ó ṣe ̀rẹ̀. 20 Lẹ́yìn wọ́n ti yọ tán kúrò nínú èérí ayé nípa mímọ́ Olúwa àti Olùgbàlà Jesu Kristi, wọn tún fi ara o, a ṣẹ́gun wọn, ìgbẹ̀yìn wọn a burú ti ìṣáájú lọ. 21 Nítorí ìbá sàn fún wọn, wọn mọ́ ̀òdodo, lẹ́yìn wọ́n mọ̀ ́n tán, wọn yípadà kúrò nínú òfin mímọ́ a fi fún wọn. 22 2.22: Òw 26.11.Òwe òtítọ́ náà ṣẹ wọn lára, "Ajá tún padà èébì ara rẹ̀; àti ẹlẹ́dẹ̀ a ti wẹ̀mọ́ tún padà ń yíràá nínú ẹrọ̀fọ̀."

Veja também

2 Pedro
Ver todos os capítulos de 2 Pedro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-