Publicidade

2 Pedro 3

Ọjọ́ Olúwa

1 Olùfẹ́, èyí ni ìwé kejì mo ń kọ yín, nínú méjèèjì náà ni èmi ń ru èrò inú yín sókè nípa rírán yín létí; 2 ̀yin máa rántí ̀rọ̀ a ti ẹnu àwọn wòlíì mímọ́ sọ ṣáájú, àti òfin Olúwa àti Olùgbàlà wa láti ̀dọ̀ àwọn aposteli yín.

3 kọ́ mọ èyí , nígbà ọjọ́ ìkẹyìn, àwọn ẹlẹ́gàn yóò pẹ̀̀gàn wọn. Wọn ó máa rìn nípa ìfẹ́ ara wọn. 4 Wọn ó máa , "Níbo ni ìlérí wíwà rẹ̀ gbé ? Láti ìgbà àwọn baba ti sùn, ohun gbogbo ń lọ wọ́n ti láti ìgbà ọjọ́ yìí ." 5 Nítorí èyí ni wọ́n mọ̀ ́n mọ̀ ṣe àìfẹ́ ́ mọ̀ nípa ̀rọ̀ Ọlọ́run ni àwọn ̀run ti láti ìgbà àtijọ́ àti ilẹ̀ yọrí jáde nínú omi, ó dúró nínú omi. 6 Nípa èyí omi bo ayé ó nígbà náà ó ṣègbé. 7 Ṣùgbọ́n àwọn ̀run àti ayé, ó ń bẹ nísinsin yìí, nípa ̀rọ̀ kan náà ni ó ti jọ ìṣúra fún iná, a pa wọ́n mọ́ de ọjọ́ ìdájọ́ àti ìparun àwọn aláìwà-bí-Ọlọ́run.

8 Ṣùgbọ́n, olùfẹ́, ṣe gbàgbé ohun kan yìí, ọjọ́ kan lọ́dọ̀ Olúwa ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún ni ó , àti ẹgbẹ̀rún (1,000) ọdún ọjọ́ kan. 9 Olúwa fi ìlérí rẹ̀ jáfara, àwọn ẹlòmíràn ti ka ìjáfara ; ṣùgbọ́n ó ń sùúrù fún yín nítorí fẹ́ ẹnikẹ́ni ṣègbé, ṣe gbogbo ènìyàn ìrònúpìwàdà.

10 Ṣùgbọ́n ọjọ́ Olúwa ń bọ̀ olè òru; nínú èyí àwọn ̀run yóò kọjá lọ pẹ̀ariwo ńlá, àti àwọn ìmọ́lẹ̀ ojú ̀run yóò ti inú ooru gbígbóná gidigidi di yíyọ́, ayé àti àwọn iṣẹ́ ó nínú rẹ̀ yóò jóná túútúú.

11 Ǹjẹ́ gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò ti yọ́ bẹ́̀, irú ènìyàn wo ni ̀yin ìbá jẹ́ nínú ìwà mímọ́ gbogbo àti ìwà-bí-Ọlọ́run. 12 máa retí, máa múra gírí de dídé ọjọ́ Ọlọ́run, nítorí èyí àwọn ̀run yóò gbiná, wọn yóò di yíyọ́, àwọn ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ yóò ti inú ooru gbígbóná gidigidi di yíyọ́. 13 Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ ìlérí rẹ̀, àwa ń retí àwọn ̀run tuntun àti ayé títún nínú èyí òdodo ń gbé.

14 Nítorí náà, olùfẹ́, ̀yin ti ń retí irú nǹkan wọ̀nyí, múra gírí, a yín àlàáfíà àìlábàwọ́n, àti àìlábùkù lójú rẹ̀. 15 máa á , sùúrù Olúwa wa ìgbàlà ni; Paulu pẹ̀arákùnrin wa olùfẹ́, ti kọ̀yín gẹ́gẹ́ ọgbọ́n a fi fún un. 16 ó ń sọ̀rọ̀ nǹkan wọ̀nyí pẹ̀nínú ìwé rẹ̀ gbogbo nínú èyí ti ohun mìíràn sọ̀rọ̀ láti ni gbé , èyí ti àwọn òpè àti àwọn aláìdúró níbìkan ń lo, wọ́n ti ń lo ìwé mímọ́ ìyókù, ìparun ara wọn.

17 Nítorí náà ̀yin olùfẹ́, ̀yin ti mọ nǹkan wọ̀nyí tẹ́lẹ̀, máa kíyèsára, a ba à fi ìṣìnà àwọn ènìyàn búburú yín lọ, ṣubú kúrò ìdúró ṣinṣin yín. 18 Ṣùgbọ́n máa dàgbà nínú oore-ọ̀fẹ́ àti nínú ìmọ̀ Olúwa àti Olùgbàlà wa Jesu Kristi.

Ẹni ògo fún nísinsin yìí àti títí láé! Àmín.

Veja também

Publicidade
2 Pedro
Ver todos os capítulos de 2 Pedro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-