Publicidade

2 Tessalonicenses 2

Ọkùnrin aláìlófin náà

1 ti bíbọ̀ Jesu Kristi Olúwa wa, àti ti ìpéjọ wa sọ́dọ̀ rẹ̀, àwa fún yín ará, 2 ọkàn yín ṣe àìbalẹ̀, tàbí ṣe jáyà nípa àsọtẹ́lẹ̀, ìròyìn tàbí lẹ́ó fi ara jọ èyí ó le láti ̀dọ̀ wa, yóò máa ọjọ́ Olúwa ti . 3 ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni ó tàn yín jẹ ̀nàkọnà, nítorí ọjọ́ náà yóò , ṣe ìṣọ̀tẹ̀ kọ́ ṣẹlẹ̀, a fi ẹni ̀ṣẹ̀ hàn, í ṣe ọmọ ègbé. 4 Òun yóò lòdì , yóò gbé ara rẹ̀ ga gbogbo ohun a ń Ọlọ́run tàbí a ń sìn, ibi yóò gbé ara rẹ̀ jókòó nínú tẹmpili Ọlọ́run, yóò pe ara rẹ̀ Ọlọ́run.

5 Ṣé ̀yin rántí nígbà mo pẹ̀yín, mo ń sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí fún un yín. 6 Àti nísinsin yìí, ̀yin mọ ohun ń a dúró, a a fi í hàn àkókò rẹ̀ gan an. 7 Nítorí agbára ìkọ̀kọ̀ ẹni ̀ṣẹ̀ ti ń ṣiṣẹ́; ṣùgbọ́n ẹni ń dènà yóò máa ṣe bẹ́̀ títí a ó fi un kúrò ̀. 8 Nígbà náà ni a ó fi ẹni ̀ṣẹ̀ hàn, ẹni Jesu Olúwa yóò fi èémí ẹnu rẹ̀ pa, yóò fi ọlá ìpadàbọ̀ rẹ̀ parun. 9 Wíwá ẹni ̀ṣẹ̀ yóò iṣẹ́ Satani, gbogbo èyí a fihàn gẹ́gẹ́ àdàmọ̀iṣẹ́ ìyanu, àdàmọ̀àmì àti àdàmọ̀idán, 10 gbogbo ̀búburú a fi ń tan àwọn ń ṣègbé jẹ. Wọ́n ṣègbé nítorí wọ́n kọ̀ láti fẹ́ràn òtítọ́ wọn di ẹni ìgbàlà. 11 Nítorí ìdí èyí, Ọlọ́run rán ohun ń ṣiṣẹ́ ìṣìnà wọn wọn gba èké gbọ́, 12 wọn ó gba ìdálẹ́bi, àní àwọn gba òtítọ́ gbọ́, ṣùgbọ́n wọ́n inú dídùn nínú ìwà búburú.

dúró ṣinṣin

13 Ṣùgbọ́n, ohun ó tọ́ fún wa ni láti máa dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nígbà gbogbo nítorí yín, ará olùfẹ́ ti Olúwa, nítorí láti ìbẹ̀rẹ̀ ni Ọlọ́run ti yàn yín ìgbàlà nípa ìsọdimímọ́ ti ̀àti nípa gbígba òtítọ́ gbọ́. 14 Òun ti yín èyí nípa ìyìnrere wa, ̀yin ó pín nínú ògo Jesu Kristi Olúwa wa.

15 Nítorí náà ará, dúró ṣinṣin, di àwọn ̀kọ́ wọ̀n-ọn-nì a kọ́ yín , yálà nípa ̀rọ̀ ẹnu tàbí lẹ́.

16 Ǹjẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa tìkálára rẹ̀, àti Ọlọ́run Baba wa, ẹni to ti fẹ́ wa, ó ti fi ìtùnú àìnípẹ̀kun àti ìrètí rere nípa oore-ọ̀fẹ́ fún wa. 17 ó ọkàn yín le, ó kún yín pẹ̀agbára nínú iṣẹ́ gbogbo àti ̀rọ̀ rere gbogbo.

Veja também

Publicidade
2 Tessalonicenses
Ver todos os capítulos de 2 Tessalonicenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-