Publicidade

Colossenses 2

1 Mo fẹ́ mọ mo ti ń jìjàkadì fún un yín àti fún àwọn ará Laodikea àti fún ̀pọ̀ ènìyàn mìíràn wọn ì ì mi sójú . 2 Ohun mo ń béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run fún un yín nínú àdúrà mi ni , a yín lọ́kàn le, a so yín pọ̀ pẹ̀ìfẹ́ to lágbára, le àṣírí ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run lẹ́kùnrẹ́rẹ́. Àṣírí ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run náà ni Kristi fúnra rẹ̀. 3 2.3: Isa 45.3.Nínú ẹni a fi gbogbo ìṣúra ìjìnlẹ̀ ọgbọ́n àti ìmọ̀ pamọ́ . 4 Mo sọ èyí fún un yín ẹnikẹ́ni ma ba à fi ̀rọ̀ ̀tàn yín ṣìnà. 5 ó tilẹ̀ jẹ́ èmi i lọ́dọ̀ yín nínú ara, ṣùgbọ́n mo lọ́dọ̀ yín nínú ̀, bẹ́̀ ni mo ń yọ̀ láti kíyèsi ètò yín àti ìdúró ṣinṣin yín nínú Kristi ti .

̀kúnrẹ́rẹ́ nínú ̀nínú Kristi

6 Nítorí náà, ̀yin ti gba Jesu Kristi gẹ́gẹ́ Olúwa, bẹ́̀ ni ̀yin máa gbé nínú rẹ̀. 7 fi gbòǹgbò múlẹ̀, a gbé yín nínú rẹ̀, fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ nínú ìgbàgbọ́ yín, a ti kọ́ yín, àti máa pọ̀ nínú rẹ̀ pẹ̀ọpẹ́.

8 dájú ẹnikẹ́ni yin ìgbèkùn pẹ̀̀kọ́ àròsọ àti ìmọ̀ ̀tàn, èyí ó gbára ìlànà ti ènìyàn àti àgbékalẹ̀ àwọn ̀ayé yìí ó yàtọ̀ ti Kristi.

9 Nítorí nínú Kristi ni ̀kúnrẹ́rẹ́ ìwàláàyè Ọlọ́run gbé ara, 10 2.10: Ef 1.21-22.̀yin ohun gbogbo kíkún nínú Kristi, ẹni i ṣe orí fún gbogbo agbára àti àṣẹ. 11 Nínú ẹni a fi ìkọlà a fi ọwọ́ kọ kọ yín ilà, ni bíbọ ara ̀ṣẹ̀ sílẹ̀, nínú ìkọlà Kristi. 12 a ti sin yín pọ̀ pẹ̀rẹ̀ nínú ìtẹ̀bọmi, a ti yín dìde pẹ̀rẹ̀ nípasẹ̀ ìgbàgbọ́ yín nínú agbára Ọlọ́run, ẹni ó dìde kúrò nínú òkú.

13 Àti ̀yin, ẹni ó ti nítorí ̀ṣẹ̀ yín àti àìkọlà ará yín, mo , ̀yin ni ó ti sọ di ààyè pọ̀ pẹ̀rẹ̀, ó ti dárí gbogbo ̀ṣẹ̀ yín yín; 14 Ó ti pa ìwé májẹ̀rẹ́, ó lòdì wa, a kọ nínú òfin, èyí o lòdì wa: òun ni ó ti kúrò lójú ̀, ó kàn án mọ àgbélébùú. 15 2.15: Ef 1.21.Ó ti gba agbára kúrò lọ́wọ́ àwọn ìjọba ̀búburú àti àwọn alágbára gbogbo, ó ti dójútì wọn gbangba, ó ti ń yọ̀ fún ìṣẹ́gun lórí wọn.

16 2.16: Ro 14.1-12. Nítorí náà ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni ṣe ìdájọ́ yín ti jíjẹ, tàbí ti mímu, tàbí ti ọjọ́ àsè, tàbí oṣù tuntun, àti ọjọ́ ìsinmi. 17 2.17: Ef 1.23.Àwọn í ṣe òjìji ohun ń bọ̀; ṣùgbọ́n ti òtítọ́, nínú Kristi ni àti mu wọn ṣẹ. 18 ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni ó inú dídùn nínú ìrẹ̀lẹ̀ èké àti bíbọ àwọn angẹli lọ́ èrè yín gbà lọ́wọ́ yín, ẹni ń dúró lórí nǹkan wọ̀n-ọn-nì ó ti , ó ń ṣe féfé asán nípa èrò ti ọkàn ara rẹ̀. 19 2.19: Ef 1.22; 4.16.Wọn ti sọ ìdàpọ̀ wọn pẹ̀ẹni i ṣe orí nu, láti ̀dọ̀ ẹni a ń ti ipa oríkèé àti iṣan pèsè fún gbogbo ara, ti a ń so ó ṣọ̀kan pọ̀, ó ń dàgbà nípa ìmísí Ọlọ́run.

20 2.20: Ga 4.3. ̀yin ti pẹ̀Kristi si àwọn agbára ìlànà ayé yìí, kín ̀yin ń tẹríba fún òfin ẹni ̀yin nínú ayé. 21 ṣe dìímú, ṣe tọ́ , ṣe fi ọwọ́ á. 22 2.22: Isa 29.13; Mk 7.7.Gbogbo èyí yóò ti ipa lílo run, gẹ́gẹ́ òfin àti ̀kọ́ ènìyàn? 23 Àwọn nǹkan ó àfarawé ọgbọ́n nítòótọ́, nípasẹ̀ àdábọwọ́ ìsìn, àti ìrẹ̀lẹ̀, àti ìpọ́nra-ẹni-lójú, ṣùgbọ́n ni èrè láti di ìfẹ́kúfẹ̀́ ara ku.

Veja também

Colossenses
Ver todos os capítulos de Colossenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-