Publicidade

Colossenses 2

1 Mo fẹ́ mọ mo ti ń jìjàkadì fún un yín àti fún àwọn ará Laodikea àti fún ̀pọ̀ ènìyàn mìíràn wọn ì ì mi sójú . 2 Ohun mo ń béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run fún un yín nínú àdúrà mi ni , a yín lọ́kàn le, a so yín pọ̀ pẹ̀ìfẹ́ to lágbára, le àṣírí ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run lẹ́kùnrẹ́rẹ́. Àṣírí ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run náà ni Kristi fúnra rẹ̀. 3 Nínú ẹni a fi gbogbo ìṣúra ìjìnlẹ̀ ọgbọ́n àti ìmọ̀ pamọ́ . 4 Mo sọ èyí fún un yín ẹnikẹ́ni ma ba à fi ̀rọ̀ ̀tàn yín ṣìnà. 5 ó tilẹ̀ jẹ́ èmi i lọ́dọ̀ yín nínú ara, ṣùgbọ́n mo lọ́dọ̀ yín nínú ̀, bẹ́̀ ni mo ń yọ̀ láti kíyèsi ètò yín àti ìdúró ṣinṣin yín nínú Kristi ti .

̀kúnrẹ́rẹ́ nínú ̀nínú Kristi

6 Nítorí náà, ̀yin ti gba Jesu Kristi gẹ́gẹ́ Olúwa, bẹ́̀ ni ̀yin máa gbé nínú rẹ̀. 7 fi gbòǹgbò múlẹ̀, a gbé yín nínú rẹ̀, fi ẹsẹ̀ múlẹ̀ nínú ìgbàgbọ́ yín, a ti kọ́ yín, àti máa pọ̀ nínú rẹ̀ pẹ̀ọpẹ́.

8 dájú ẹnikẹ́ni yin ìgbèkùn pẹ̀̀kọ́ àròsọ àti ìmọ̀ ̀tàn, èyí ó gbára ìlànà ti ènìyàn àti àgbékalẹ̀ àwọn ̀ayé yìí ó yàtọ̀ ti Kristi.

9 Nítorí nínú Kristi ni ̀kúnrẹ́rẹ́ ìwàláàyè Ọlọ́run gbé ara, 10 ̀yin ohun gbogbo kíkún nínú Kristi, ẹni i ṣe orí fún gbogbo agbára àti àṣẹ. 11 Nínú ẹni a fi ìkọlà a fi ọwọ́ kọ kọ yín ilà, ni bíbọ ara ̀ṣẹ̀ sílẹ̀, nínú ìkọlà Kristi. 12 a ti sin yín pọ̀ pẹ̀rẹ̀ nínú ìtẹ̀bọmi, a ti yín dìde pẹ̀rẹ̀ nípasẹ̀ ìgbàgbọ́ yín nínú agbára Ọlọ́run, ẹni ó dìde kúrò nínú òkú.

13 Àti ̀yin, ẹni ó ti nítorí ̀ṣẹ̀ yín àti àìkọlà ará yín, mo , ̀yin ni ó ti sọ di ààyè pọ̀ pẹ̀rẹ̀, ó ti dárí gbogbo ̀ṣẹ̀ yín yín; 14 Ó ti pa ìwé májẹ̀rẹ́, ó lòdì wa, a kọ nínú òfin, èyí o lòdì wa: òun ni ó ti kúrò lójú ̀, ó kàn án mọ àgbélébùú. 15 Ó ti gba agbára kúrò lọ́wọ́ àwọn ìjọba ̀búburú àti àwọn alágbára gbogbo, ó ti dójútì wọn gbangba, ó ti ń yọ̀ fún ìṣẹ́gun lórí wọn.

16 Nítorí náà ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni ṣe ìdájọ́ yín ti jíjẹ, tàbí ti mímu, tàbí ti ọjọ́ àsè, tàbí oṣù tuntun, àti ọjọ́ ìsinmi. 17 Àwọn í ṣe òjìji ohun ń bọ̀; ṣùgbọ́n ti òtítọ́, nínú Kristi ni àti mu wọn ṣẹ. 18 ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni ó inú dídùn nínú ìrẹ̀lẹ̀ èké àti bíbọ àwọn angẹli lọ́ èrè yín gbà lọ́wọ́ yín, ẹni ń dúró lórí nǹkan wọ̀n-ọn-nì ó ti , ó ń ṣe féfé asán nípa èrò ti ọkàn ara rẹ̀. 19 Wọn ti sọ ìdàpọ̀ wọn pẹ̀ẹni i ṣe orí nu, láti ̀dọ̀ ẹni a ń ti ipa oríkèé àti iṣan pèsè fún gbogbo ara, ti a ń so ó ṣọ̀kan pọ̀, ó ń dàgbà nípa ìmísí Ọlọ́run.

20 ̀yin ti pẹ̀Kristi si àwọn agbára ìlànà ayé yìí, kín ̀yin ń tẹríba fún òfin ẹni ̀yin nínú ayé. 21 ṣe dìímú, ṣe tọ́ , ṣe fi ọwọ́ á. 22 Gbogbo èyí yóò ti ipa lílo run, gẹ́gẹ́ òfin àti ̀kọ́ ènìyàn? 23 Àwọn nǹkan ó àfarawé ọgbọ́n nítòótọ́, nípasẹ̀ àdábọwọ́ ìsìn, àti ìrẹ̀lẹ̀, àti ìpọ́nra-ẹni-lójú, ṣùgbọ́n ni èrè láti di ìfẹ́kúfẹ̀́ ara ku.

Veja também

Publicidade
Colossenses
Ver todos os capítulos de Colossenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-