Publicidade

Daniel 4

Nebukadnessari àlá nípa igi

1 Nebukadnessari ọba,

gbogbo ènìyàn, orílẹ̀ àti onírúurú èdè, ó ń gbé àgbáyé.

àlàáfíà máa pọ̀ i fún un yín.

ṣe rere pọ̀!

2 Ó jẹ́ ìdùnnú fún mi láti fi iṣẹ́ àmì àti ìyanu Ọlọ́run ̀gá-Ògo ti ṣe fún mi hàn.

3 Báwo ni àmì rẹ̀ ti tóbi ,

báwo ni ìyanu rẹ̀ ṣe pọ̀ !

Ìjọba rẹ̀, ìjọba títí ayé ni;

ilẹ̀ ọba rẹ̀ láti ìran ìran ni.

4 Èmi Nebukadnessari ààfin mi, pẹ̀ìtẹ́lọ́rùn àti àlàáfíà. 5 Mo àlá kan èyí ó lẹ́. Nígbà mo lórí ibùsùn mi, ìran ó jáde lọ́kàn mi dẹ́rùbà . 6 Nígbà náà, ni mo pàṣẹ a gbogbo àwọn amòye Babeli , wọn sọ ìtumọ̀ àlá náà fún mi. 7 Nígbà àwọn apidán, àwọn apògèdè, àwọn awòràwọ̀ àti àwọn aláfọ̀ṣẹ , mo sọ àlá náà fún wọn, ṣùgbọ́n wọn le è sọ ìtumọ̀ àlá náà fún mi. 8 ìkẹyìn Daniẹli síwájú mi, mo sọ àlá náà fún. (Ẹni à ń Belṣassari gẹ́gẹ́ orúkọ òrìṣà mi àti ̀àwọn ọlọ́run mímọ́ nínú rẹ̀.)

9 Mo , "Belṣassari, olórí àwọn amòye, èmi mọ̀ ̀ọlọ́run mímọ́ nínú rẹ, ṣí àṣírí kan ó ṣòro fún . Sọ àlá mi o túmọ̀ rẹ̀ fún mi. 10 Èyí ni ìran náà mo nígbà mo lórí ibùsùn mi, mo igi kan láàrín ayé, igi náà ga gidigidi. 11 Igi náà tóbi, ó lágbára, orí rẹ̀ ń kan ̀run; a i títí òpin ayé. 12 4.12,21: El 17.23; 31.6; Mt 13.32; Mk 4.32; Lk 13.19.Ewé rẹ̀ lẹ́, èso rẹ̀ pọ̀, ó ń pèsè oúnjẹ fún gbogbo ènìyàn. Abẹ́ rẹ̀ ni àwọn ẹranko igbó fi ṣe ibùgbé, àwọn ẹyẹ ojú ̀run ń gbé ̀ka rẹ̀, nínú rẹ̀ ni gbogbo alààyè ti ń jẹ.

13 "Lórí ibùsùn mi, mo ìran náà, olùṣọ́ kan dúró síwájú u mi, àní ẹni mímọ́ kan, ó ń bọ̀ láti ̀run 14 ó kígbe sókè , igi náà o àwọn ̀ka rẹ̀ kúrò; gbọn ewé rẹ̀ , o fọ́n èso rẹ̀ dànù. Jẹ́ àwọn ẹranko ó lábẹ́ rẹ̀ àti àwọn ẹyẹ ó ̀ka rẹ̀ kúrò. 15 Ṣùgbọ́n fi kùkùté àti gbòǹgbò rẹ̀ a fi irin àti idẹ ṣẹ́sórí ilẹ̀ àti orí koríko igbó.

" Jẹ́ ìrì ̀run sẹ̀ i lára, ó jẹ́ ìpín in rẹ̀ pẹ̀àwọn ẹranko igbó láàrín ilẹ̀ ayé. 16 Jẹ́ ọkàn rẹ̀ ó padà kúrò ti ènìyàn, a fún un ọkàn ẹranko, títí ìgbà méje yóò fi kọjá lórí i rẹ̀.

17 " Olùṣọ́ ni ó gbé ìpinnu náà jáde, àṣẹ láti ̀dọ̀ ẹni mímọ́, gbogbo alààyè le mọ̀ , ̀gá-ògo ni olórí ìjọba ènìyàn, ó ń fi fún ẹnikẹ́ni ó ú, òun ń gbé onírẹ̀lẹ̀ lórí i wọn.

18 "Èyí ni àlá èmi Nebukadnessari ọba . ìsinsin yìí ìwọ Belṣassari, sọ ohun ó túmọ̀ fún mi, nítorí amòye kan ìjọba mi, ó sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi. Ṣùgbọ́n ìwọ sọ ìtumọ̀ rẹ̀, nítorí ̀Ọlọ́run mímọ́ inú rẹ."

Daniẹli túmọ̀ àlá náà

19 Nígbà náà ni Daniẹli (ẹni à ń Belṣassari) páyà gidigidi fún ìgbà díẹ̀, èrò inú rẹ̀ á lẹ́. Nígbà náà ni ọba , "Belṣassari, ṣe jẹ́ àlá náà tàbí ìtumọ̀ rẹ̀ ó dẹ́rùbà ́."

Belṣassari dáhùn , "Olúwa mi, àlá yìí jẹ́ ti àwọn ̀a rẹ, ìtumọ̀ rẹ̀ jẹ́ ti àwọn aṣòdì . 20 Igi ìwọ , ó dàgbà, ó lágbára, orí rẹ̀ ń kan ̀run, ó lẹ́àti ̀pọ̀lọpọ̀ èso, ó ń pèsè oúnjẹ fún gbogbo ènìyàn, ó ṣe ààbò lórí ẹranko igbó àti èyí ̀ka rẹ̀ pèsè ààyè fún ẹyẹ ojú ̀run. 21 Èyí ewé e rẹ̀ lẹ́, èso rẹ̀ si pọ̀, nínú èyí oúnjẹ fún gbogbo ̀, lábẹ́ èyí àwọn ẹranko igbó ń gbé, lórí ̀ka èyí ti àwọn ẹyẹ ojú ̀run ibùgbé wọn. 22 Ìwọ ọba ni igi náà, ìwọ ti dàgbà, o lágbára, títóbi i rẹ ga ó kan ̀run, ìjọba rẹ gbilẹ̀ títí òpin ayé.

23 "Ìwọ ọba, ìránṣẹ́ ẹni mímọ́ kan, ó ń bọ̀ láti ̀run ó sọ , igi náà o run ún, ṣùgbọ́n fi kùkùté rẹ a pẹ̀irin àti idẹ sílẹ̀ nínú koríko igbó, nígbà gbòǹgbò rẹ̀ nínú ilẹ̀ o jẹ́ ìrì ̀run sẹ̀ sórí i rẹ̀, jẹ́ ìpín in rẹ̀ láàrín ẹranko búburú títí ìgbà méje yóò fi kọjá lórí i rẹ̀.’

24 "Èyí ni ìtumọ̀ àlá rẹ ọba àti àṣẹ ̀gá-ògo sórí ọba olúwa mi. 25 A ó jáde kúrò láàrín ènìyàn, ìwọ yóò máa gbé láàrín ẹranko búburú, ìwọ yóò jẹ koríko i màlúù, ìrì ̀run yóò sẹ̀ sára rẹ. Ìgbà méje yóò kọjá lórí rẹ, títí ìwọ yóò fi mọ̀ ̀gá-ògo ń jẹ ọba lórí ìjọba ènìyàn, ó ń fi fún ẹni ó ú. 26 wọ́n ṣe pàṣẹ wọn fi kùkùté àti gbòǹgbò igi náà sílẹ̀, èyí túmọ̀ a ó ìjọba rẹ padà fún lẹ́yìn ìgbà o ti mọ̀ , ̀run jẹ ọba. 27 Nítorí náà ọba, jẹ́ ìmọ̀ràn mi jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún , kọ ̀ṣẹ̀ rẹ sílẹ̀ o ṣe rere, àti ìwà búburú rẹ nípa ṣíṣe àánú fún àwọn tálákà. Ó jẹ́ nígbà náà ni ìwọ yóò ṣe rere."

Àlá náà ṣẹ

28 Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ṣẹlẹ̀ Nebukadnessari ọba. 29 Lẹ́yìn oṣù kejìlá, ọba ṣe ń rìn káàkiri lórí òrùlé ààfin ìjọba Babeli, 30 ó sọ , "Èyí ha kọ́ ni Babeli ńlá mo kọ́ gẹ́gẹ́ ilé ọba, nípa agbára à mi àti fún ògo ọláńlá à mi?"

31 ọba ṣe ń sọ ̀rọ̀ náà lọ́wọ́ ohùn kan láti ̀run, "Ìwọ Nebukadnessari ọba, ìwọ ni a ti pàṣẹ nípa rẹ̀, a ti gba ìjọba à rẹ kúrò ọwọ́ ̀ rẹ. 32 A ó kúrò láàrín àwọn ènìyàn, ìwọ yóò lọ máa gbé àárín àwọn ẹranko igbó; ìwọ yóò jẹ koríko i màlúù, ìgbà méje yóò kọjá lórí i rẹ títí ìwọ yóò fi mọ̀ , ̀gá-ògo jẹ ọba lórí ìjọba ènìyàn àti ó ń fi fún ẹni ó ú."

33 Lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ ni ohun a sọ nípa Nebukadnessari ṣẹlẹ̀ i. A e kúrò láàrín ènìyàn, ó ń jẹ koríko i màlúù, ìrì ̀run ń sẹ̀ ara rẹ̀, títí irun orí rẹ̀ fi gùn i ti ìyẹ́ ẹyẹ idì, èékánná rẹ̀ dàbí i ti ẹyẹ.

34 òpin ìgbà náà, èmi, Nebukadnessari gbé ojú mi sókè ̀run, iyè mi sọjí. Mo fi ọpẹ́ fún ̀gá-ògo; mo fi ọlá àti ògo fún ẹni ó láéláé.

Ìjọba rẹ̀ ìjọba títí ayé ni

ìjọba rẹ̀ láti ìran ìran.

35 Gbogbo àwọn ènìyàn ayé

ni a asán.

Ó ń ṣe ó ti ú,

pẹ̀àwọn ogun ̀run,

àti gbogbo àwọn ènìyàn ayé

ṣí ẹnìkankan ó i lọ́wọ́

tàbí sọ fún un : "ni ìwọ ń ṣe?"

36 àkókò kan náà, iyè mi padà, ọlá àti ògo dídán mi padà tọ̀ fún ògo ìjọba mi. Àwọn ìgbìmọ̀ àti àwọn ọlọ́mi, mi , wọ́n mi padà sórí ìjọba mi, mo di alágbára ju ti ìṣáájú lọ. 37 Báyìí, èmi, Nebukadnessari fi ọpẹ́, mo gbé Ọlọ́run ga, mo fi ògo fún ọba ̀run, nítorí gbogbo nǹkan ó ṣe dára, gbogbo ̀rẹ̀ tọ́. Gbogbo àwọn ń rìn ìgbéraga ni ó le rẹ̀ sílẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-