Publicidade

Efésios 2

Ìṣọdààyè nínú Kristi

1 ti ̀yin, ̀yin ni ó ti sọ di ààyè, nígbà ti ̀yin ti nítorí ìrékọjá àti àwọn ̀ṣẹ̀ yín, 2 nínú èyí ̀yin ti gbé , àní ìlànà ti ayé yìí, gẹ́gẹ́ aláṣẹ agbára ojú ̀run, ̀n ṣiṣẹ́ ni ìsinsin yìí nínú àwọn ọmọ aláìgbọ́ràn. 3 Nínú àwọn ẹni gbogbo wa pẹ̀ti nínú ìfẹ́kúfẹ̀́ ara wa, a ń ìfẹ́ ara àti ti inú ṣẹ, àti nípa ìṣẹ̀àwa ti jẹ́ ọmọ ìbínú, gẹ́gẹ́ àwọn ìyókù pẹ̀. 4 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run, ẹni í ṣe ọlọ́rọ̀ ni àánú, nítorí ìfẹ́ ńlá rẹ̀ ó fi fẹ́ wa, 5 nígbà àwa tilẹ̀ ti nítorí ìrékọjá wa, ó sọ di ààyè pẹ̀Kristi, oore-ọ̀fẹ́ ni a ti fi gbà yín . 6 Ọlọ́run ti wa dìde pẹ̀Kristi, ó ti wa jókòó pẹ̀rẹ̀ nínú àwọn ̀run nínú Kristi Jesu. 7 ni gbogbo ìgbà ń bọ̀ ó á fi ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ o pọ̀ rékọjá hàn fún wa nínú ìṣeun rẹ̀ nínú Kristi Jesu. 8 Nítorí oore-ọ̀fẹ́ a fi gbà yín nípa ìgbàgbọ́. Èyí í ṣe nípa agbára ̀yin fúnra yín: ̀bùn Ọlọ́run ni, 9 í ṣe nípa àwọn iṣẹ́, ẹnikẹ́ni ba à ṣògo. 10 Nítorí àwa ni iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ a ti nínú Kristi Jesu fún àwọn iṣẹ́ rere, èyí Ọlọ́run ti pèsè tẹ́lẹ̀, fún wa láti ṣe.

̀kan nínú Kristi

11 Nítorí náà rántí , nígbà àtijọ́ , ̀yin ti jẹ́ Kèfèrí nípa ti ìbí, àwọn a ń "aláìkọlà" láti ọwọ́ àwọn ń pe ara wọn "akọlà" (èyí ti a fi ọwọ́ ènìyàn ṣe ni ara). 12 rántí ni àkókò náà ̀yin láìní Kristi, jẹ́ àjèjì Israẹli, àti àjèjì àwọn májẹ̀ìlérí náà, láìní ìrètí, àti láìní Ọlọ́run ni ayé. 13 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí nínú Kristi Jesu ̀yin ó ti jìnà réré nígbà àtijọ́ ni a súnmọ́ tòsí, nípa ̀jẹ̀ Kristi.

14 Nítorí òun ni àlàáfíà wa, ẹni o ti ṣe méjèèjì ni ̀kan, ó ti ògiri ìkélé ti ìkórìíra èyí ń bẹ láàrín yín. 15 Ó ti fi òpin ̀náà nínú ara rẹ̀, àní òfin àti àṣẹ wọ̀n-ọn-nì ń bẹ nínú ìlànà, ó sọ àwọn méjèèjì di ẹni tuntun kan nínú ara rẹ̀, ó ṣe ìlàjà 16 àti ó àwọn méjèèjì Ọlọ́run làjà nínú ara kan nípa àgbélébùú; nípa èyí yóò fi pa ìṣọ̀náà run. 17 Ó ti , ó ti wàásù àlàáfíà fún ̀yin o jìnnà réré, àti àlàáfíà fún àwọn o súnmọ́ tòsí. 18 Nítorí nípa rẹ̀ ni àwa méjèèjì ti ni àǹfààní sọ́dọ̀ baba nípa ̀kan.

19 Ǹjẹ́ nítorí náà ̀yin í ṣe àlejò àti àjèjì mọ́, ṣùgbọ́n àjùmọ̀jogún ọmọ ìbílẹ̀ pẹ̀àwọn ènìyàn mímọ́, àti àwọn ará ilé Ọlọ́run; 20 a ń gbé yín lórí ìpìlẹ̀ àwọn aposteli, àti àwọn wòlíì, pẹ̀Jesu Kristi fúnra rẹ̀ gẹ́gẹ́ pàtàkì òkúta igun ilé. 21 Nínú rẹ ni gbogbo ilé náà, a ń kọ papọ̀ ṣọ̀kan ó ń dàgbàsókè láti di tẹmpili mímọ́ kan nínú Olúwa. 22 Nínú rẹ̀ ni a ń gbé ̀yin pẹ̀pẹ̀fún ibùjókòó Ọlọ́run nínú ̀rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-