Publicidade

Efésios 4

Ìṣọ̀kan nínú ara Jesu

1 Nítorí náà, èmi òǹdè nínú Olúwa ń bẹ̀ yín ̀yin máa gbé ìgbé ayé ó yẹ ìpè a yín . 2 Pẹ̀ìrẹ̀lẹ̀ gbogbo àti inú tútù, pẹ̀ìpamọ́ra, máa fi ìfẹ́ faradà fún ẹnìkejì yín. 3 máa làkàkà láti pa ìṣọ̀kan ̀mọ́ ni ìdàpọ̀ àlàáfíà. 4 Ara kan ni ń bẹ, àti ̀kan, àní a ti yín sínú ìrètí kan nígbà a yín. 5 Olúwa kan, ìgbàgbọ́ kan àti ìtẹ̀bọmi kan. 6 Ọlọ́run kan àti Baba gbogbo aráyé, ẹni ó ṣe olórí ohun gbogbo àti nípá gbogbo àti nínú ohun gbogbo.

7 Ṣùgbọ́n olúkúlùkù wa ni a fi oore-ọ̀fẹ́ fun gẹ́gẹ́ bi òsùwọ̀n ̀bùn Kristi. 8 Nítorí náà a :

"Nígbà ó gòkè lọ ibi gíga,

ó di ìgbèkùn ni ìgbèkùn,

ó fi ̀bùn fun ènìyàn."

9 (Ǹjẹ́ ti , "Ó gòkè lọ!" Kín ni ó túmọ̀ , ṣe ó kọ́ sọ̀kalẹ̀ pẹ̀lọ ìsàlẹ̀ ilẹ̀? 10 Ẹni ó ti sọ̀kalẹ̀, Òun kan náà ni ó ti gòkè rékọjá gbogbo àwọn ̀run, ó kún ohun gbogbo.) 11 Nítorí náà ó ti fi àwọn kan fún ni aposteli; àti àwọn mìíràn i wòlíì; àti àwọn mìíràn efangelisti, àti àwọn mìíràn olùṣọ́-àgùntàn àti olùkọ́ni. 12 Fún àṣepé àwọn ènìyàn mímọ́ fun iṣẹ́ ìránṣẹ́, fún ìmúdàgbà ara Kristi. 13 Títí gbogbo wa yóò fi ìṣọ̀kan ìgbàgbọ́ àti ìmọ̀ Ọmọ Ọlọ́run, títí a ó fi di ọkùnrin, títí a ó fi ̀kúnrẹ́rẹ́ ìwọ̀n Kristi.

14 àwa ṣe jẹ́ èwe mọ́, a ń fi gbogbo afẹ́fẹ́ ̀kọ́ síwá sẹ́yìn, a fi ń gbá kiri, nípa ìtànjẹ ènìyàn, nípa àrékérekè fun ọgbọ́nkọ́gbọ́n àti ni ṣìnà. 15 Ṣùgbọ́n a máa sọ òtítọ́ ìfẹ́, a máa dàgbàsókè nínú rẹ̀ ohun gbogbo ẹni i ṣe orí, àní Kristi. 16 Láti ̀dọ̀ ẹni ti ara náà a ń so ṣọ̀kan pọ̀, ó ń fi ara mọ́ra, nípasẹ̀ oríkèé kọ̀̀kan a ti pèsè, nígbà ̀kọ̀̀kan ń ṣiṣẹ́ dáradára, yóò ara dàgbà, yóò gbé ara òun tìkára rẹ̀ dìde nínú ìfẹ́.

Gbígbé ìgbé ayé gẹ́gẹ́ ọmọ ìmọ́lẹ̀

17 Ǹjẹ́ èyí ni mo ń , mo ń jẹ́rìí nínú Olúwa , láti ìsinsin yìí lọ, ̀yin ṣe rìn mọ́, àní gẹ́gẹ́ àwọn aláìkọlà ti ń rìn nínú ìrònú asán wọn. 18 Òye àwọn ẹni ó ṣókùnkùn, a wọ́n nínú ìyè Ọlọ́run nítorí àìmọ̀ ń bẹ nínú wọn, nítorí líle ọkàn wọn. 19 Àwọn ẹni ọkàn wọn le rékọjá, wọ́n ti fi ara wọn fún wọ̀bìà, láti máa fi ìwọra ṣiṣẹ́ ìwà èérí gbogbo.

20 Ṣùgbọ́n a fi Kristi kọ́ yín bẹ́̀. 21 ó ṣe nítòótọ́ ni ti gbóhùn rẹ̀ ti a ti kọ́ yín nínú rẹ̀, gẹ́gẹ́ òtítọ́ ti ń bẹ nínú Jesu. 22 , ìwà yín àtijọ́, ̀yin bọ́ ògbólógbòó ọkùnrin sílẹ̀, èyí ó díbàjẹ́ gẹ́gẹ́ ìfẹ́kúfẹ̀́ ̀tàn; 23 di tuntun ni ̀inú yín; 24 gbé ọkùnrin tuntun ni wọ̀, èyí a ni àwòrán Ọlọ́run nínú òdodo àti ìwà mímọ́ ti òtítọ́.

25 Nítorí náà fi èké ṣíṣe sílẹ̀, ki olúkúlùkù yín ó máa ba ọmọnìkejì rẹ̀ sọ òtítọ́, nítorí ̀ara ọmọnìkejì wa ni àwa jẹ́. 26 Nínú ìbínú yín, máa ṣe ṣẹ̀, ṣe jẹ́ oòrùn wọ̀ ìbínú yín, 27 bẹ́̀ ni ṣe fi ààyè ̀gbẹ́ kan fún Èṣù. 28 ẹni ń jalè ṣe jalè mọ́: ṣùgbọ́n ó kúkú máa ṣe làálàá, ó máa fi ọwọ́ rẹ̀ ṣiṣẹ́ ohun ó dára, òun láti pín fún ẹni ó ṣe aláìní.

29 ṣe jẹ́ ̀rọ̀ ìdíbàjẹ́ kan ti ẹnu yín jáde, ṣùgbọ́n irú èyí ó ràn ìdàgbàsókè wọn lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ ohun wọ́n nílò, ó máa fi oore-ọ̀fẹ́ fún àwọn ń gbọ́. 30 ṣe ̀Mímọ́ Ọlọ́run bínú, ẹni a fi ṣe èdìdì yín ọjọ́ ìdáǹdè. 31 Gbogbo ìwà kíkorò àti ìbínú, àti ìrunú, àti ariwo, àti ̀rọ̀ búburú ni a kúrò lọ́dọ̀ yín, pẹ̀gbogbo àrankàn. 32 máa ṣoore fún ọmọnìkejì yín, ìyọ́, máa dáríjì ara yín, gẹ́gẹ́ Ọlọ́run nínú Kristi ti dáríjì yín.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-