Publicidade

Filemom 1

Ìkíni

1 Èmi Paulu, ẹni a fi sẹ́wọ̀n nítorí ó ń wàásù ìyìnrere Jesu Kristi àti Timotiu arákùnrin wa,

Filemoni ̀rẹ́ wa ̀wọ́n àti alábáṣiṣẹ́ wa, 2 Affia arábìnrin wa, Arkippu ẹni jẹ́ jagunjagun fún àgbélébùú náà àti ìjọ àwọn Kristiani ó ń pàdé nínú ilé rẹ:

3 Oore-ọ̀fẹ́ fún un yín àti àlàáfíà láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa àti Jesu Kristi.

Ìdúpẹ́ àti àdúrà

4 Èmi máa ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nígbà mo rántí rẹ nínú àdúrà mi, 5 nítorí mo ń gbọ́ nípa ìgbàgbọ́ rẹ nínú Jesu Olúwa àti nípa ìfẹ́ rẹ àwọn ènìyàn mímọ́. 6 Èmi ń gbàdúrà , ìwọ ti ń ṣe alábápín nínú ìgbàgbọ́ rẹ pẹ̀àwọn ẹlòmíràn, ìgbàgbọ́ náà ọkàn wọn dúró gbọingbọin, gẹ́gẹ́ wọn ti àwọn ̀rọ̀ ohun rere ó ń bẹ nínú ayé rẹ, èyí ó ti ̀dọ̀ Kristi . 7 Ìfẹ́ rẹ ti fún mi ayọ̀ púpọ̀ àti ìgboyà, nítorí ìwọ, arákùnrin ti tu ọkàn àwọn ènìyàn mímọ́ lára.

Paulu bẹ̀bẹ̀ fún Onesimu

8 Nítorí náà, ó tilẹ̀ jẹ́ nínú Kristi mo ìgboyà púpọ̀ láti pàṣẹ ohun ti ó yẹ ó ṣe fún , 9 síbẹ̀ nítorí ìfẹ́ èmí kúkú bẹ̀ ́. Èmi gẹ́gẹ́ Paulu, arúgbó, àti nísinsin yìí òǹdè Jesu Kristi. 10 Èmí bẹ̀ ́ nítorí ọmọ mi Onesimu, ẹni ó di ọmọ nígbà mo nínú ìdè. 11 Nígbà kan , wúlò fún , ṣùgbọ́n báyìí, ó ti wúlò fún àti fún èmi pàápàá.

12 Èmi rán an nísinsin yìí, àní ẹni ọkàn mi padà ̀dọ̀ rẹ. 13 Èmi ìbá fẹ́ láti a dúró sọ́dọ̀ mi níhìn-ín, ó ba à dípò rẹ láti máa ràn lọ́wọ́ nígbà mo nínú ìdè nítorí ìyìnrere 14 ṣùgbọ́n èmi fẹ́ ṣe bẹ́̀ rárá láìgba ìyọ̀ǹda ọwọ́ rẹ, oore ìwọ ṣe ba à jẹ́ ìfipámúniṣe ṣe ìfìfẹ́ṣe. 15 Bóyá ìdí rẹ̀ òun fi yẹra kúrò lọ́dọ̀ rẹ fún ìgbà díẹ̀ ni ìwọ ó gbà á padà sọ́dọ̀ títí láé. 16 í ṣe ẹrú mọ́, ṣùgbọ́n ẹni ti ó sàn ju ẹrú lọ, gẹ́gẹ́ arákùnrin. Ó ṣọ̀wọ́n fún mi jọjọ, ṣùgbọ́n ó ṣọ̀wọ́n fún nípa ti ara àti gẹ́gẹ́ arákùnrin nínú Olúwa.

17 Nítorí náà ìwọ ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, tẹ́wọ́ gbà á ìwọ yóò ti tẹ́wọ́ gbà . 18 ó ti ṣe ́ ibi kan tàbí jẹ ́ gbèsè ohun kan, á mi lọ́rùn. 19 Èmi Paulu, ni mo fi ọwọ́ ara mi kọ ìwé yìí; èmi yóò san án padà láì tilẹ̀ í sọ nípa ìwọ pàápàá jẹ mi gbèsè ara rẹ. 20 Èmi ń fẹ́ arákùnrin, èmi ó ni àǹfààní kan láti ̀dọ̀ rẹ nínú Olúwa; fi ayọ̀ rẹ kún ọkàn mi nínú Kristi. 21 Ìgbẹ́kẹ̀ti mo ìwọ yóò gbọ́rọ̀, ni mo fi kọ ìwé yìí ránṣẹ́ . Mo mọ̀ dájú ìwọ yóò ṣe ju mo ti béèrè lọ.

22 Ó ku ohun kan, ṣe ìtọ́iyàrá àlejò rẹ sílẹ̀ fún mi, nítorí mo ìgbàgbọ́ a óò mi sílẹ̀ fún yín ìdáhùn àdúrà yín.

23 Epafira, òǹdè ẹlẹgbẹ́ mi nínú Kristi Jesu . 24 Marku pẹ̀Aristarku, Dema àti Luku, àwọn alábáṣiṣẹ́ mi.

25 oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa pẹ̀̀yín.

Veja também

Publicidade
Filemom
Ver todos os capítulos de Filemom
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-