Publicidade

Filipenses 1

1 Paulu àti Timotiu, àwọn ìránṣẹ́ Jesu Kristi,

gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́ nínú Kristi Jesu ó Filipi, pẹ̀àwọn alábojútó àti àwọn díákónì:

2 Oore-ọ̀fẹ́ yín, àti àlàáfíà láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wa, àti Olúwa wa Jesu Kristi.

Ìdúpẹ́ àti àdúrà

3 Mo ń dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run mi gbogbo ìgbà mo rántí yín. 4 Nínú gbogbo àdúrà mi fún un yín, èmi ń fi ayọ̀ gbàdúrà, 5 nítorí ìdàpọ̀ yín nínú ìyìnrere láti ọjọ́ kìn-ín-ní títí di ìsinsin yìí. 6 Ohun kan yìí à mi lójú , ẹni ó ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rere nínú yín, yóò ṣe àṣepé rẹ̀ títí di ọjọ́ náà Jesu Kristi yóò .

7 Gẹ́gẹ́ ó ti tọ́ fún mi láti ro èyí nípa gbogbo yín, nítorí mo fi yín sọ́kàn, mo tilẹ̀ nínú ìdè tàbí ìdáhùn ẹjọ́, àti ìfẹsẹ̀múlẹ̀ ìyìnrere, gbogbo yín jẹ́ alábápín oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run pẹ̀mi. 8 Nítorí Ọlọ́run ni ẹlẹ́rìí mi, mo ti ń ṣàfẹ́yín gidigidi nínú ìfẹ́ Jesu Kristi.

9 Èyí ni àdúrà mi: ìfẹ́ yín máa pọ̀ síwájú àti síwájú i nínú ìfẹ́ àti ìmọ̀ ìjìnlẹ̀, 10 ̀yin ó òye ohun ó dára jùlọ; ó jásí òdodo àti aláìjẹ́ ohun ìkọ̀sẹ̀ títí di ọjọ́ dídé Jesu Kristi, 11 lẹ́yìn ìgbà ti ti kún fún àwọn ìwà òdodo láti ̀dọ̀ Jesu Kristi, fún ògo àti ìyìn Ọlọ́run.

Ìrírí Paulu nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́

12 Ǹjẹ́ èmi fẹ́ ̀yin ó mọ̀, ará, ohun ó ṣẹlẹ̀ mi jásí àtẹ̀gùn ìlọsíwájú ìyìnrere. 13 Nítorí ìdí èyí, ó ti hàn gbangba gbogbo àwọn ̀ṣọ́ ààfin àti àwọn ẹlòmíràn mo nínú ìdè fún Kristi. 14 Nítorí ìdè mi, ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ará nínú Olúwa ni a ti lọ́kàn le láti sọ̀rọ̀ Ọlọ́run i pẹ̀ìgboyà àti láìbẹ̀.

15 Òtítọ́ ni àwọn ẹlòmíràn tilẹ̀ ń fi ìjà àti ìlara wàásù Kristi, ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn ń fi inú rere ṣe é. 16 Àwọn kan ń fi ìjà wàásù Kristi, í ṣe pẹ̀òtítọ́ inú, wọ́n ń gbèrò láti fi ìpọ́njú kún ìdè mi. 17 Àwọn kan ̀wẹ̀ si ń fi ìfẹ́ ṣe é, nítorí wọ́n mọ̀ a gbé mi dìde láti ààbò bo iṣẹ́ ìyìnrere. 18 tún ? Kìkì í níbi gbogbo, ìbá à ìfẹ̀tànṣe tàbí ni ti òtítọ́ a à n wàásù Kristi, èmi ń yọ̀ nítorí èyí.

Nítòótọ́, èmi ó máa yọ̀, 19 nítorí mo mọ̀ èyí ni yóò yọrí ìgbàlà fún mi láti inú àdúrà yín , àti ìfikún ̀Jesu Kristi. 20 Gẹ́gẹ́ ìfẹ́ ọkàn àti ìrètí mi ojú ó ṣe ti mi ohunkóhun, ṣùgbọ́n èmi ó le máa ni ìgboyà ìgbà gbogbo àti nísinsin yìí, a ti ipasẹ̀ mi gbé Kristi ga lára mi, ìbá à ṣe mo láààyè, tàbí mo . 21 Nítorí, ti èmi, láti wa láààyè jẹ́ Kristi, láti pẹ̀jẹ́ èrè fún mi. 22 Ṣùgbọ́n èmi le è ṣe iṣẹ́ ti ó ni àpẹẹrẹ nípa wíwà láààyè nínú ara, ṣùgbọ́n ohun ti èmi ó yàn, èmi mọ̀. 23 Ṣùgbọ́n èmi n ṣiyèméjì, nítorí ti èmi fẹ́ láti lọ kúrò nínú ayé yìí, láti lọ́dọ̀ Kristi; nítorí ó dára púpọ̀ : 24 síbẹ̀ láti láààyè jẹ́ àǹfààní nítorí tiyín. 25 èyí ti mi lójú, mo mọ̀ èmi ó dúró, èmi ó máa pẹ̀yín fún ìtẹ̀síwájú àti ayọ̀ yín nínú ìgbàgbọ́, 26 ìṣògo yín ó di púpọ̀ gidigidi nínú Jesu Kristi, àti nínú mi nípa ìpadà mi sọ́dọ̀ yín.

̀rọ̀ ìyànjú

27 Ohun yówù ṣẹlẹ̀, jẹ́ ìgbé ayé yín ri gẹ́gẹ́ ìyìnrere Kristi: yálà bi mo tilẹ̀ yín, tàbí èmi , èmi ó máa gbúròó ti ń ṣe, ̀yin dúró ṣinṣin nínú ̀kan, ̀yin jùmọ̀ jìjàkadì nítorí ìgbàgbọ́ ìyìnrere, pẹ̀ọkàn kan. 28 jẹ́ ki àwọn ̀dẹ́rùbà yin ni ohunkóhun: èyí í ṣe àmì ó dájú a ó pa wọ́n run, ṣùgbọ́n Ọlọ́run tìkára rẹ̀ ni yóò gbà yin . 29 Nítorí a ti fún yin ni àǹfààní, í ṣe láti gba Kristi gbọ́ nìkan, ṣùgbọ́n láti jìyà nítorí rẹ̀ pẹ̀. 30 máa ja ìjà kan náà, èyí ti ̀yin ti ri, ti ti gbọ́ èmi n pẹ̀.

Veja também

Publicidade
Filipenses
Ver todos os capítulos de Filipenses
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-