Publicidade

Gálatas 1

1 Paulu, aposteli a rán í ṣe láti ̀dọ̀ ènìyàn , tàbí nípa ènìyàn, ṣùgbọ́n nípa Jesu Kristi àti Ọlọ́run Baba, ẹni ó i dìde kúrò nínú òkú. 2 Àti gbogbo àwọn arákùnrin ó pẹ̀mi,

àwọn ìjọ Galatia:

3 Oore-ọ̀fẹ́ yín àti àlàáfíà láti ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba àti Jesu Kristi Olúwa, 4 ẹni ó fi òun tìkára rẹ̀ dípò ̀ṣẹ̀ wa, ó gbà kúrò nínú ayé búburú ìsinsin yìí, gẹ́gẹ́ ìfẹ́ Ọlọ́run àti Baba wa, 5 ẹni ògo fún láé àti láéláé. Àmín.

ìyìnrere mìíràn

6 Ó mi lẹ́nu tètè yapa kúrò lọ́dọ̀ ẹni ó yín sínú oore-ọ̀fẹ́ Kristi, ìyìnrere mìíràn. 7 Nítòótọ́, ìyìnrere mìíràn ó tilẹ̀ ṣe àwọn kan , ń yọ yín lẹ́nu, wọ́n ń fẹ́ ìyìnrere Kristi padà. 8 Ṣùgbọ́n ó ṣe àwa ni tàbí angẹli kan láti ̀run , ni ó wàásù ìyìnrere mìíràn fún yín ju èyí a wàásù rẹ̀ fún yín lọ, jẹ́ ó di ẹni ìfibú títí láéláé! 9 àwa ti ṣáájú, bẹ́̀ ni mo tún nísinsin yìí , ẹnìkan wàásù ìyìnrere mìíràn fún yín ju èyí ̀yin gbà lọ, jẹ́ ó di ẹni ìfibú títí láéláé!

10 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ènìyàn ni èmi ń ojúrere rẹ̀ tàbí Ọlọ́run? Tàbí ènìyàn ni èmi ń fẹ́ láti ? èmi ń fẹ́ láti wu ènìyàn, èmi jẹ́ ìránṣẹ́ Kristi.

Paulu ẹni Ọlọ́run

11 Mo fẹ́ mọ̀, ará, ìyìnrere mo wàásù í ṣe láti ipa ènìyàn. 12 N gbà á lọ́wọ́ ènìyàn kankan, bẹ́̀ ni a fi kọ́ mi, ṣùgbọ́n mo gbà á nípa ìfihàn láti ̀dọ̀ Jesu Kristi.

13 Nítorí ̀yin ti gbúròó ìgbé ayé mi nígbà àtijọ́ nínú ìsìn àwọn Júù, mo ṣe inúnibíni ìjọ ènìyàn Ọlọ́run rékọjá ààlà, mo lépa láti á jẹ́. 14 Mo ta ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ẹlẹgbẹ́ mi yọ nínú ìsìn àwọn Júù láàrín àwọn ìran mi, mo ni ìtara lọ́pọ̀lọ́pọ̀ òfin àtọwọ́dọ́wọ́ àwọn baba mi. 15 Ṣùgbọ́n nígbà ó Ọlọ́run ẹni ó sọ́tọ̀ láti inú ìyá mi , ó mi nípa oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀. 16 Láti fi ọmọ rẹ̀ hàn nínú mi, èmi máa wàásù ìyìnrere rẹ̀ láàrín àwọn aláìkọlà; èmi ìmọ̀ lọ sọ́dọ̀ ẹnikẹ́ni, 17 bẹ́̀ ni èmi gòkè lọ Jerusalẹmu tọ àwọn í ṣe aposteli ṣáájú mi, ṣùgbọ́n mo lọ Arabia, mo tún padà Damasku.

18 Lẹ́yìn ọdún mẹ́ta, nígbà náà ni mo gòkè lọ Jerusalẹmu láti lọ Peteru, mo gbé ̀dọ̀ rẹ̀ ìjọ mẹ́̀́dógún, 19 èmi ri ẹlòmíràn nínú àwọn ó jẹ́ aposteli, ṣe Jakọbu arákùnrin Olúwa. 20 Nǹkan èmi ń kọ̀yín yìí, kíyèsi i, níwájú Ọlọ́run èmi ṣèké.

21 Lẹ́yìn náà mo agbègbè Siria àti ti Kilikia. 22 Mo jẹ́ ẹni a mọ̀ lójú fún àwọn ìjọ ó nínú Kristi ni Judea. 23 Wọ́n kàn gbọ́ ìròyìn , "Ẹni ó ń ṣe inúnibíni wa , ìsinsin yìí ti ń wàásù ìgbàgbọ́ náà ó ti gbìyànjú láti bàjẹ́ nígbà kan ." 24 Wọ́n yin Ọlọ́run lógo nítorí mi.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-