Publicidade

Gálatas 4

1 Ǹjẹ́ ohun mo ń ni , níwọ̀n ìgbà àrólé náà èwe, yàtọ̀ nínú ohunkóhun ẹrú ó tilẹ̀ jẹ́ Olúwa ohun gbogbo. 2 Ṣùgbọ́n ó lábẹ́ olùtọ́àti ìríjú títí àkókò baba ti yàn tẹ́lẹ̀. 3 4.3: Kl 2.20.Gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni àwa, nígbà àwa èwe, àwa nínú ìdè lábẹ́ ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé. 4 Ṣùgbọ́n nígbà àkókò kíkún náà , Ọlọ́run rán ọmọ rẹ̀ jáde , ẹni a nínú obìnrin a lábẹ́ òfin. 5 Láti ra àwọn ń bẹ lábẹ́ òfin padà, àwa gba ìsọdọmọ. 6 4.6: Ro 8.15.Àti nítorí ̀yin jẹ́ ọmọ, Ọlọ́run ti rán ̀Ọmọ rẹ̀ sínú ọkàn yín, ń , "Ábbà, Baba." 7 Nítorí náà ìwọ í ṣe ẹrú, ṣe ọmọ; àti ìwọ ń ṣe ọmọ, ǹjẹ́ ìwọ di àrólé Ọlọ́run nípasẹ̀ Kristi.

Ìtara Paulu fún àwọn ará Galatia

8 Tẹ́lẹ̀tẹ́lẹ̀, nígbà ̀yin i mọ Ọlọ́run, ̀yin ti ṣe ẹrú fún àwọn í ṣe Ọlọ́run nípa ìṣẹ̀. 9 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, nígbà ̀yin ti mọ Ọlọ́run tan tàbí a kúkú di mímọ́ fún Ọlọ́run, èéha ti tún fi yípadà aláìlera àti agbára ìpilẹ̀ṣẹ̀ ̀, lábẹ́ èyí ̀yin tún fẹ́ padà ṣe ẹrú? 10 ̀yin ń kíyèsi ọjọ́ àti àkókò, àti ọdún. 11 ̀yin ń , o ṣe lásán ni mo ṣe làálàá lórí yín.

12 Ará, mo bẹ̀ yín, dàbí èmi: nítorí èmi dàbí ̀yin: ̀yin ṣe ibi kan. 13 4.13: Ap 16.6.̀yin mọ̀ nínú àìlera ni mo wàásù ìyìnrere fún yín àkọ́kọ́. 14 Èyí ó jẹ́ ìdánwò fún yín ara mi ni kẹ́gàn, bẹ́̀ ni kọ̀; ṣùgbọ́n ̀yin gbà angẹli Ọlọ́run, àní Kristi Jesu. 15 Ǹjẹ́ ayọ̀ yín ìgbà náà ha ? Nítorí mo gba ̀yín , bi o ṣe é ṣe, ̀ ò yọ ojú yín jáde, ̀ fi wọ́n fún mi. 16 Ǹjẹ́ mo ha di ̀yín nítorí mo sọ òtítọ́ fún yín ?

17 Wọ́n ń fi ìtara yin, ṣùgbọ́n í ṣe fún rere; wọ́n ń fẹ́ yin kúrò, ̀yin máa wọn. 18 Ṣùgbọ́n ó dára láti máa fi ìtara ni fún ohun rere nígbà gbogbo, í í ṣe nígbà mo pẹ̀yín nìkan. 19 4.19: 1Kọ 4.15.̀yin ọmọ mi kéékèèké, ̀yin mo tún ń rọbí títí a ó fi ṣe ̀Kristi nínú yín. 20 Ìbá láti lọ́dọ̀ yín nísinsin yìí, èmi ohùn mi padà nítorí mo dààmú nítorí yín.

Hagari àti Sara

21 fún mi, ̀yin ń fẹ́ lábẹ́ òfin, ko ha gbọ́ òfin ohun ti òfin sọ. 22 4.22: Gẹ 16.15; 21.2,9.Nítorí a ti kọ ́ , Abrahamu ọmọ ọkùnrin méjì, ̀kan láti ̀dọ̀ ẹrúbìnrin, àti ̀kan láti ̀dọ̀ òmìnira obìnrin. 23 4.23: Ro 9.7-9.Ṣùgbọ́n a èyí ṣe ti ẹrúbìnrin nípa ti ara, ṣùgbọ́n èyí ti òmìnira obìnrin ni a nípa ìlérí.

24 Nǹkan wọ̀nyí jẹ́ àpẹẹrẹ: nítorí àwọn obìnrin wọ̀nyí májẹ̀méjèèjì; ̀kan láti orí òkè Sinai , a lóko ẹrú, í ṣe Hagari. 25 Nítorí Hagari yìí ni òkè Sinai Arabia, ó dúró fún Jerusalẹmu ó nísinsin yìí, ó lóko ẹrú pẹ̀àwọn ọmọ rẹ̀. 26 Ṣùgbọ́n Jerusalẹmu ti òkè jẹ́ òmìnira, èyí í ṣe ìyá wa. 27 4.27: Isa 54.1.Nítorí a ti kọ ́ ,

"Máa yọ̀, ìwọ obìnrin àgàn

bímọ,

ayọ̀ o kígbe sókè,

ìwọ rọbí ;

nítorí àwọn ọmọ obìnrin náà a kọ̀sílẹ̀

yóò pọ̀ ju ti obìnrin ọkọ lọ."

28 Ǹjẹ́ ará, ọmọ ìlérí ni àwa gẹ́gẹ́ Isaaki. 29 4.29: Gẹ 21.9.Ṣùgbọ́n èyí a nípa ti ara ti ṣe inúnibíni nígbà náà èyí a nípa ti ̀, bẹ́̀ ni nísinsin yìí. 30 4.30: Gẹ 21.10-12.Ṣùgbọ́n ìwé mímọ́ ha ti , "ẹrúbìnrin yìí àti ọmọ rẹ̀ jáde, nítorí ọmọ ẹrúbìnrin yóò ọmọ òmìnira obìnrin jogún pọ̀." 31 Nítorí náà, ará, àwa í ṣe ọmọ ẹrúbìnrin ṣe ti òmìnira obìnrin.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-