Publicidade

Gálatas 6

Ṣíṣe dáradára gbogbo ènìyàn

1 Ará, a tilẹ̀ ènìyàn nínú ̀ṣẹ̀ kan, ̀yin í ṣe ti ̀irú ẹni bẹ́̀ bọ̀ sípò nínú ̀ìwà tútù; ìwọ tìkára rẹ̀ máa kíyèsára, a ba à dán ìwọ náà pẹ̀. 2 máa ru ẹrù ọmọnìkejì yín, fi bẹ́̀ òfin Kristi ṣẹ. 3 Nítorí ènìyàn kan ń ro ara rẹ̀ ẹnìkan, nígbà jẹ́ nǹkan, ó ń tan ara rẹ̀ jẹ. 4 Ṣùgbọ́n olúkúlùkù yẹ iṣẹ́ ara rẹ̀ , nígbà náà, ohun ìmú-ṣogo rẹ̀ yóò jẹ́ nínú ti ara rẹ̀ nìkan, yóò jẹ nínú ti ọmọnìkejì rẹ̀. 5 Nítorí olúkúlùkù ni yóò ru ẹrù ara rẹ̀. 6 Ṣùgbọ́n ẹni a ń kọ́ nínú ̀rọ̀ náà máa pèsè ohun rere gbogbo fún ẹni ń kọ́ni.

7 a ṣe tàn yín jẹ; a gan Ọlọ́run: nítorí ohunkóhun ènìyàn fúnrúgbìn, òhun ni yóò . 8 Nítorí ẹni ó ń fúnrúgbìn sípa ti ara yóò ìdíbàjẹ́ ti ara ṣùgbọ́n ẹni ń fúnrúgbìn sípa ti ̀yóò ti inú ̀ìyè àìnípẹ̀kun. 9 jẹ́ àárẹ̀ ọkàn wa ṣíṣe rere, nítorí a ó kórè nígbà àkókò , a ṣe àárẹ̀. 10 Ǹjẹ́ a ti ń àǹfààní gba, jẹ́ a máa ṣoore fún gbogbo ènìyàn, àti pàápàá fún àwọn í ṣe ará ilé ìgbàgbọ́.

í ṣe ìkọlà ṣe ̀tuntun

11 wo mo ti fi ọwọ́ ara mi kọ̀gàdàgbà-gàdàgbà yín.

12 Iye àwọn ń fẹ́ ṣe àṣehàn ni ara wọn ń rọ yín láti kọlà; kìkì nítorí a ba à ṣe inúnibíni wọn nítorí àgbélébùú Kristi. 13 Nítorí àwọn a kọ ilà pàápàá pa òfin mọ́, ṣùgbọ́n wọ́n ń fẹ́ yin kọlà, wọn máa ṣògo nínú ara yín. 14 Ṣùgbọ́n a ṣe i èmi ń ṣògo, ṣe nínú àgbélébùú Jesu Kristi Olúwa wa, nípasẹ̀ ẹni a ti kan ayé mọ́ àgbélébùú fún mi, àti èmi fún ayé. 15 Nítorí nínú Kristi Jesu, ìkọlà jẹ́ ohun kan, tàbí àìkọlà, ṣe ̀tuntun. 16 àlàáfíà àti àánú lórí gbogbo àwọn ń rìn ìlànà yìí, àti lórí Israẹli Ọlọ́run.

17 Láti ìsinsin yìí lọ, ẹnikẹ́ni ṣe yọ lẹ́nu mọ́; nítorí èmi ń ru àpá Jesu Olúwa kiri ara mi.

Oore-ọ̀fẹ́

18 Ará, oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa, ó pẹ̀̀yín. Àmín.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-