Publicidade

Hebreus 10

35 Nítorí náà ṣe gbé ìgboyà yín sọnù, èyí ti o ni èrè ńlá.

36 Nítorí ̀yin le ṣe aláìní sùúrù, nítorí ìgbà ̀yin ti ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run tan ̀yin le gba ìlérí náà. 37 Nítorí,

"Ni ìwọ̀n ìgbà díẹ̀ i,

ẹni náà ti ń bọ̀ yóò ,

yóò jáfara.

38 Ṣùgbọ́n,

"Olódodo ni yóò nípa ìgbàgbọ́.

Ṣùgbọ́n o ba fàsẹ́yìn,

ọkàn mi inú dídùn i."

39 Ṣùgbọ́n àwa nínú àwọn ń fàsẹ́yìn sínú ègbé; ṣe nínú àwọn o gbàgbọ́ ìgbàlà ọkàn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-