Publicidade

Hebreus 12

5 12.5-8: Òw 3.11-12.̀yin ti gbàgbé ̀rọ̀ ìyànjú ó n ba yin sọ̀rọ̀ ọmọ ,

"Ọmọ mi, ma ṣe aláìnání ìbáwí Olúwa,

o ṣe rẹ̀wẹ̀nígbà a ń ti ọwọ́ rẹ̀ ba ,

6 nítorí ẹni ti Olúwa fẹ́, òun ni i ,

a máa na olúkúlùkù ọmọ òun tẹ́wọ́gbà."

7 máa sùúrù lábẹ́ ìbáwí, Ọlọ́run wa ọmọ ni; nítorí ọmọ wo ni ń bẹ ti baba í ? 8 Ṣùgbọ́n ̀yin ba láìsí ìbáwí, nínú èyí gbogbo ènìyàn ti jẹ alábápín, ǹjẹ́ ọmọ àlè ni yín, í ṣe ọmọ. 9 Pẹ̀lúpẹ̀àwa ni baba wa nípa ti ara o ń tọ́ wa, àwa ń bu ọlá fún wọn: ha yẹ a kúkú tẹríba fún Baba àwọn ̀, a ?

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_23-13-58-