Publicidade

Hebreus 3

Jesu pọ̀ ju Mose lọ

1 Nítorí náà ̀yin ará mímọ́, alábápín ìpè ̀run, gba ti aposteli àti olórí àlùfáà ìjẹ́wọ́ wa , àní Jesu; 2 ẹni o ṣe olóòtítọ́ si ẹni ó yàn án, Mose pẹ̀ṣe olóòtítọ́ nínú iṣẹ́ rẹ̀ gbogbo nínú ilé Ọlọ́run. 3 Nítorí a ka ọkùnrin yìí ni yíyẹ ògo ju Mose lọ níwọ̀n ẹni ó kọ́ ilé ti lọ́ju ilé lọ. 4 Láti ọwọ́ ènìyàn kan ni a à ti kọ́ olúkúlùkù ilé; ṣùgbọ́n ẹni ó kọ́ ohun gbogbo ni Ọlọ́run. 5 Mose nítòótọ́ ṣe olóòtítọ́ nínú gbogbo iṣẹ́ rẹ̀ nínú ilé Ọlọ́run, ìránṣẹ́, fún ̀ohun a ó sọ̀rọ̀ wọ́n ìgbà ìkẹyìn. 6 Ṣùgbọ́n Kristi jẹ́ olóòtítọ́ gẹ́gẹ́ ọmọ lórí ilé Ọlọ́run; ilé ẹni àwa jẹ́, àwa gbẹ́kẹ̀e, a di ìṣògo ìrètí wa mu ṣinṣin títí òpin.

Ìkìlọ̀ fún aláìgbàgbọ́

7 Nítorí náà gẹ́gẹ́ bi ̀Mímọ́ :

"Lónìí ̀yin gbọ́ ohùn rẹ̀,

8 ṣe ọkàn yín le,

ìgbà ìṣọ̀tẹ̀,

i ọjọ́ ìdánwò aginjù,

9 níbi àwọn baba yín ti dán mi ,

wọ́n iṣẹ́ mi ogójì ọdún.

10 Nítorí náà a inú mi si ìran náà,

mo , Nígbà gbogbo ni wọn ṣìnà ọkàn wọn;

wọn mọ ̀mi.

11 mo búra nínú ìbínú mi,

Wọn yóò wọ inú ìsinmi mi.’ "

12 kíyèsára, ará, ọkàn búburú ti àìgbàgbọ́ ṣe nínú ẹnikẹ́ni yín, lílọ kúrò lọ́dọ̀ Ọlọ́run alààyè. 13 Ṣùgbọ́n máa gba ara yín ìyànjú ojoojúmọ́, níwọ̀n ìgbà a ń "Òní," a ba à ọkàn ẹnikẹ́ni nínú yín le nípa ̀tàn ̀ṣẹ̀. 14 Nítorí àwa di alábápín pẹ̀Kristi, àwa di ìpilẹ̀ṣẹ̀ ìgbẹ́kẹ̀wa ṣinṣin títí òpin. 15 Nígbà a ń ,

"Lónìí ̀yin gbọ́ ohùn rẹ̀,

ọkàn yin le,

ìgbà ìṣọ̀tẹ̀."

16 Àwọn ta ni ó gbọ́ ó tún ṣọ̀tẹ̀? í ha ṣe gbogbo àwọn o jáde kúrò Ejibiti abẹ́ àkóso Mose? 17 Àwọn ta ni ó bínú fún ogójì ọdún? í ha ṣe àwọn ó dẹ́ṣẹ̀, òkú àwọn ó sùn aginjù? 18 Àwọn wo ni ó búra fún wọn yóò wọ inú ìsinmi òun, ṣe fún àwọn ó ṣe àìgbọ́ràn? 19 Àwa i wọn wọ inú rẹ̀ nítorí àìgbàgbọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-