Publicidade

João 10

Agbo kan àti olùṣọ́-àgùntàn kan

1 "Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo fún yín, ẹni gba ẹnu-ọ̀wọ inú agbo àgùntàn, ṣùgbọ́n ó gba ibòmíràn gun òkè, òun náà ni olè àti ọlọ́ṣà. 2 Ṣùgbọ́n ẹni ó ti ẹnu-ọ̀wọlé, Òun ni olùṣọ́ àwọn àgùntàn. 3 Òun ni aṣọ́yóò ṣílẹ̀kùn fún; àwọn àgùntàn gbọ́ ohùn rẹ̀, ó pe àwọn àgùntàn tirẹ̀ lórúkọ, ó ṣe amọ̀wọn jáde. 4 Nígbà ó ti àwọn àgùntàn tirẹ̀ jáde, yóò síwájú wọn, àwọn àgùntàn yóò máa tọ̀ ́ lẹ́yìn, nítorí wọ́n mọ ohùn rẹ̀. 5 Wọn jẹ́ tọ àlejò lẹ́yìn, ṣùgbọ́n wọn a kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, nítorí wọn mọ ohùn àlejò." 6 Òwe yìí ni Jesu pa fún wọn, ṣùgbọ́n òye ohun nǹkan wọ̀nyí ó ń sọ fún wọn wọn.

7 Nítorí náà Jesu tún fún wọn , "Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo fún yín, Èmi ni ìlẹ̀kùn àwọn àgùntàn. 8 Olè àti ọlọ́ṣà ni gbogbo àwọn ó ti ṣáájú mi, ṣùgbọ́n àwọn àgùntàn gbọ́ tiwọn. 9 Èmi ni ìlẹ̀kùn, ẹnìkan ̀dọ̀ mi wọlé, òun ni a ó gbàlà, yóò wọlé, yóò jáde, yóò koríko. 10 Olè í ṣe láti jalè, láti pa, àti láti parun; èmi wọn ìyè, àní wọn i lọ́pọ̀lọ́pọ̀.

11 "Èmi ni olùṣọ́-àgùntàn rere, olùṣọ́-àgùntàn rere fi ọkàn rẹ̀ lélẹ̀ nítorí àwọn àgùntàn. 12 Ṣùgbọ́n alágbàṣe, í ṣe olùṣọ́-àgùntàn, ẹni àwọn àgùntàn í ṣe tirẹ̀, ó ìkookò ń bọ̀, ó fi àgùntàn sílẹ̀, ó fọ́n wọn kiri. 13 Òun sálọ nítorí ó jẹ́ alágbàṣe, náání àwọn àgùntàn.

14 "Èmi ni olùṣọ́-àgùntàn rere, mo mọ àwọn tèmi, àwọn tèmi mọ̀ . 15 Gẹ́gẹ́ Baba ti mọ̀ , èmi mọ Baba, mo fi ọkàn mi lélẹ̀ nítorí àwọn àgùntàn. 16 Èmi àwọn àgùntàn mìíràn, í ṣe agbo yìí: àwọn ni èmi yóò pẹ̀, wọn yóò gbọ́ ohùn mi; wọn ó jẹ́ agbo kan, olùṣọ́-àgùntàn kan. 17 Nítorí náà ni Baba mi ṣe fẹ́ràn mi, nítorí mo fi ̀mi lélẹ̀, èmi tún gbà á. 18 Ẹnìkan gbà á lọ́wọ́ mi, ṣùgbọ́n mo fi í lélẹ̀, mo lágbára láti tún gbà á. Àṣẹ yìí ni mo ti gbà láti ̀dọ̀ Baba mi."

19 Nítorí náà ìyapa tún láàrín àwọn Júù nítorí ̀rọ̀ wọ̀nyí. 20 ̀pọ̀ nínú wọn , "Ó ̀èṣù, orí rẹ̀ dàrú; èéṣe ̀yin fi ń gbọ́rọ̀ rẹ̀?"

21 Àwọn mìíràn , "Ìwọ̀nyí í ṣe ̀rọ̀ ẹni ó ̀èṣù. ̀èṣù la ojú àwọn afọ́?"

Àìgbàgbọ́ àwọn Júù

22 Àkókò náà jẹ́ àjọ̀dún ìyàsímímọ́ Jerusalẹmu, ni ìgbà òtútù. 23 Jesu ń rìn tẹmpili, ìloro Solomoni. 24 Nítorí náà àwọn Júù dúró i , wọ́n fún un , "Ìwọ ó ti wa ṣe iyèméjì pẹ́ ? ìwọ ni Kristi náà, fún wa gbangba."

25 Jesu wọn lóhùn , "Èmi ti fún yín, ̀yin gbàgbọ́; iṣẹ́ èmi ń ṣe lórúkọ Baba mi, àwọn ni ó ń jẹ́rìí mi. 26 Ṣùgbọ́n ̀yin gbàgbọ́, nítorí ̀yin nínú àwọn àgùntàn mi, gẹ́gẹ́ mo fún yín. 27 Àwọn àgùntàn mi ń gbọ́ ohùn mi, èmi mọ̀ wọ́n, wọn a máa tọ̀ lẹ́yìn. 28 Èmi fún wọn ìyè àìnípẹ̀kun; wọn yóò ṣègbé láéláé, ẹni ó wọn gbà kúrò lọ́wọ́ mi. 29 Baba mi, ẹni ó fi wọ́n fún mi pọ̀ ju gbogbo wọn lọ; ṣí ẹni ó wọn gbà kúrò lọ́wọ́ Baba mi. 30 ̀kan ni èmi àti Baba mi."

31 Àwọn Júù tún òkúta, láti sọ ú. 32 Jesu wọn lóhùn , "̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ rere ni mo fihàn yín láti ̀dọ̀ Baba mi , nítorí èwo nínú iṣẹ́ wọ̀nyí ni ̀yin ṣe sọ òkúta?"

33 Àwọn Júù a lóhùn , "Àwa sọ ́ lókùúta nítorí iṣẹ́ rere, ṣùgbọ́n nítorí ̀rọ̀-òdì, àti nítorí ìwọ í ṣe ènìyàn ń fi ara rẹ pe Ọlọ́run."

34 Jesu wọn lóhùn , "A ha kọ ́ nínú òfin yín , Mo ti , Ọlọ́run ni ̀yin jẹ́’? 35 ó wọ́n ọlọ́run,àwọn ẹni a fi ̀rọ̀ Ọlọ́run fún, a ba ìwé mímọ́ jẹ́. 36 Kín ni ẹyin ha ń ti ẹni Baba sọ́tọ̀, ó rán ayé kín lo de ti fi ̀sùn kàn mi ń sọ̀rọ̀-òdì nítorí mo sọ , Èmi ni Ọmọ Ọlọ́run. 37 èmi ṣe iṣẹ́ Baba mi, ṣe gbà gbọ́. 38 Ṣùgbọ́n èmi ṣe wọ́n, ̀yin tilẹ̀ gbà gbọ́, gbà iṣẹ́ náà gbọ́, ̀yin ba à mọ̀, ó yín , Baba nínú mi, èmi nínú rẹ̀." 39 Wọ́n tún ń ̀láti un: ó bọ́ lọ́wọ́ wọn.

40 Ó tún kọjá lọ apá kejì Jordani ibi Johanu ti kọ́kọ́ ń bamitiisi; níbẹ̀ ni ó jókòó. 41 Àwọn ènìyàn púpọ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n , "Johanu ṣe iṣẹ́ àmì kan, Ṣùgbọ́n òtítọ́ ni ohun gbogbo Johanu sọ nípa ti ọkùnrin yìí." 42 Àwọn ènìyàn púpọ̀ níbẹ̀ gbà á gbọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-