Publicidade

João 15

Àjàrà àti ̀ka rẹ̀

1 "Èmi ni àjàrà tòótọ́, Baba mi ni olùṣọ́gbà. 2 Gbogbo ̀ka nínú mi so èso, òun a kúrò, gbogbo ̀ka ó so èso, òun a wẹ̀ ́ mọ́, ó so èso i. 3 ̀yin mọ́ nísinsin yìí nítorí ̀rọ̀ mo ti sọ fún yín. 4 máa gbé inú mi, èmi ó máa gbé inú yín. Gẹ́gẹ́ ̀ka ti so èso fún ara rẹ̀ ṣe ó ba ń gbé inú àjàrà, bẹ́̀ ni ̀yin, ṣe ń gbé inú mi.

5 "Èmi ni àjàrà, ̀yin ni ̀ka. Ẹni ó ń gbé inú mi, àti èmi nínú rẹ̀, òun ni yóò so èso lọ́pọ̀lọ́pọ̀, nítorí yíya ara yín kúrò lọ́dọ̀ mi, ṣe ohun kan. 6 ẹnìkan gbé inú mi, a gbé e sọnù gẹ́gẹ́ ̀ka, a gbẹ; wọn a wọn jọ, wọn a sọ wọ́n sínú iná, wọn a jóná. 7 ̀yin ń gbé inú mi, ̀rọ̀ mi gbé inú yín, ó béèrè ohunkóhun fẹ́, a ó ṣe é fún yín. 8 Nínú èyí a yìn Baba mi lógo , ̀yin ó máa so èso púpọ̀; ̀yin ó jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn mi.

9 "Gẹ́gẹ́ Baba ti fẹ́ mi, bẹ́̀ ni èmi fẹ́ yín, dúró nínú ìfẹ́ rẹ̀. 10 ̀yin pa òfin mi mọ́, ó dúró nínú ìfẹ́ mi; gẹ́gẹ́ èmi ti pa òfin Baba mi mọ́, mo dúró nínú ìfẹ́ rẹ̀. 11 Nǹkan wọ̀nyí ni mo ti sọ fún yín, ayọ̀ mi ó nínú yín, àti ayọ̀ yín ó kún. 12 Èyí ni òfin mi, ̀yin ó fẹ́ràn ara yín, gẹ́gẹ́ mo ti fẹ́ràn yín. 13 ẹnìkan ó ìfẹ́ ó tóbi ju èyí lọ, ẹnìkan fi ̀rẹ̀ lélẹ̀ nítorí àwọn ̀rẹ́ rẹ̀. 14 ̀rẹ́ mi ni ̀yin ń ṣe, ṣe ohun èmi pàṣẹ fún yín. 15 Èmi yín ọmọ ̀dọ̀ mọ́; nítorí ọmọ ̀dọ̀ mọ ohun olúwa rẹ̀ ń ṣe, ṣùgbọ́n èmi yín ̀rẹ́ nítorí ohun gbogbo mo ti gbọ́ láti ̀dọ̀ Baba mi , mo ti fihàn fún yín. 16 í ṣe ̀yin ni ó yàn , ṣùgbọ́n èmi ni ó yàn yín, mo fi yín sípò, ̀yin ó lọ, so èso, àti èso yín dúró; ohunkóhun béèrè lọ́wọ́ Baba orúkọ mi, ó fi í fún yín. 17 Nǹkan wọ̀nyí ni mo pàṣẹ fún yín , ̀yin ó fẹ́ràn ara yín.

Ayé kórìíra àwọn ọmọ-ẹ̀yìn

18 "ayé kórìíra yín, mọ̀ , ó ti kórìíra mi ṣáájú yín. 19 Ìbá ṣe ̀yin ń ṣe ti ayé, ayé ìbá fẹ́ yin bi àwọn tirẹ̀; gẹ́gẹ́ bi o ṣe ri ̀yin ń ṣe ti ayé, ṣùgbọ́n èmi ti yàn yín kúrò nínú ayé, nítorí èyí ni ayé ṣe kórìíra yín. 20 rántí ̀rọ̀ mo ti sọ fún yín , Ọmọ ̀dọ̀ tóbi ju olúwa rẹ̀ lọ.wọ́n ti ṣe inúnibíni mi, wọ́n ó ṣe inúnibíni yín pẹ̀: wọ́n ti pa ̀rọ̀ mi mọ́, wọ́n ó pa tiyín mọ́ pẹ̀. 21 Ṣùgbọ́n gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni wọ́n yóò ṣe yín, nítorí orúkọ mi, nítorí wọn mọ ẹni ó rán mi. 22 Ìbá ṣe èmi ti n ti wọn sọ̀rọ̀, wọn ̀ṣẹ̀, ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n di aláìríwí fún ̀ṣẹ̀ wọn. 23 Ẹni ó kórìíra mi, ó kórìíra Baba mi pẹ̀. 24 Ìbá ṣe èmi ti ṣe iṣẹ́ wọ̀n-ọn-nì láàrín wọn ẹlòmíràn ṣe , wọn ̀ṣẹ̀, ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n , wọ́n kórìíra èmi àti Baba mi. 25 Ṣùgbọ́n èyí bẹ́̀ ̀rọ̀ a kọ nínú òfin wọn ó ṣẹ , Wọ́n kórìíra mi àìnídìí.

26 "Ṣùgbọ́n nígbà Olùtùnú náà , ẹni èmi ó rán yín láti ̀dọ̀ Baba , àní ̀òtítọ́ , ń ti ̀dọ̀ Baba , òun náà ni yóò jẹ́rìí mi. 27 ̀yin pẹ̀yóò jẹ́rìí mi, nítorí ̀yin ti pẹ̀mi láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ .

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-