Pular para o conteúdo
Publicidade

João 19

A Jesu lẹ́bi láti kàn mọ àgbélébùú

1 Nítorí náà ni Pilatu Jesu, ó án. 2 19.2-3: Mt 27.27-31; Mk 15.16-20; Lk 22.63-65; 23.11.Àwọn ọmọ-ogun hun adé ̀gún, wọ́n fi e orí, wọ́n fi aṣọ ìgúnwà elése àlùkò wọ̀ ́. 3 Wọ́n , "Kábíyèsí, ọba àwọn Júù!" Wọ́n fi ọwọ́ wọn gbá a ojú.

4 19.4: Jh 18.38; 19.6; Lk 23.4. Pilatu tún jáde, ó fún wọn , "ó, mo u jáde tọ̀ yín , ̀yin ó mọ̀ , èmi ̀ṣẹ̀ kan lọ́wọ́ rẹ̀." 5 Nítorí náà Jesu jáde , ti òun ti adé ̀gún àti aṣọ elése àlùkò. Pilatu fún wọn , "ọkùnrin náà!"

6 Nítorí náà nígbà àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn oníṣẹ́ i, wọ́n kígbe , "Kàn án mọ́ àgbélébùú, kàn án mọ́ àgbélébùú."

Pilatu fún wọn , "un fún ara yín, kàn án mọ́ àgbélébùú: nítorí èmi ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀."

7 19.7: Le 24.16; Mk 14.61-64; Jh 5.18; 10.33. Àwọn Júù a lóhùn , "Àwa òfin kan, àti gẹ́gẹ́ òfin, wa ó yẹ fún un láti , nítorí ó gbà Ọmọ Ọlọ́run ni òun ń ṣe."

8 Nítorí náà nígbà Pilatu gbọ́ ̀rọ̀ yìí, ̀túbọ̀ á. 9 Ó tún wọ inú gbọ̀ngàn ìdájọ́ lọ, ó fún Jesu , "Níbo ni ìwọ ti ?" Ṣùgbọ́n Jesu a lóhùn. 10 Nítorí náà, Pilatu fún un , "Èmi ni ìwọ fọhùn ? Ìwọ mọ̀ , èmi agbára láti sílẹ̀, èmi agbára láti kàn ́ mọ́ àgbélébùú?"

11 19.11: Ro 13.1; Jh 18.28. Jesu a lóhùn , "Ìwọ agbára kan lórí mi, ṣe a fi í fún láti òkè , nítorí náà ẹni ó fi lọ́wọ́ ni ó ̀ṣẹ̀ pọ̀."

12 19.12: Lk 23.2. Nítorí èyí, Pilatu ń ̀láti a sílẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn Júù kígbe, , "ìwọ ọkùnrin yìí sílẹ̀, ìwọ í ṣe ̀rẹ́ Kesari: ẹnikẹ́ni ó ṣe ara rẹ̀ ọba, ó sọ̀rọ̀-òdì Kesari."

13 Nítorí náà nígbà Pilatu gbọ́ ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó Jesu jáde , ó jókòó lórí ìtẹ́ ìdájọ́ ibi a ń Òkúta-títẹ́, ṣùgbọ́n èdè Heberu, Gabata. 14 19.14: Mk 15.42; Jh 19.31,42; Mk 15.25,33.Ó jẹ́ ìpalẹ̀mọ́ àjọ ìrékọjá, ó jẹ́ ìwọ̀n wákàtí ̀kẹfà:

Ó fún àwọn Júù , "wo ọba yín!"

15 Nítorí náà wọ́n kígbe , "un kúrò, un kúrò. Kàn án mọ́ àgbélébùú."

Pilatu fún wọn , "Èmi yóò ha kan ọba yín mọ́ àgbélébùú ?"

Àwọn olórí àlùfáà dáhùn , "Àwa ọba ṣe Kesari."

16 Nítorí náà ni Pilatu á wọn lọ́wọ́ láti kàn án mọ́ àgbélébùú.

Wọ́n kan Jesu mọ́ àgbélébùú

Àwọn ológun gba Jesu lọ́wọ́ Pilatu. 17 19.17-24: Mt 27.33-44; Mk 15.22-32; Lk 23.33-43.Nítorí náà, wọ́n Jesu, ó jáde lọ, ó ru àgbélébùú fúnra rẹ̀ ibi à ń ibi agbárí, èdè Heberu à ń Gọlgọta. 18 Níbi wọ́n gbé kàn án mọ́ àgbélébùú, àti àwọn méjì mìíràn pẹ̀rẹ̀, níhà ìhín àti níhà kejì, Jesu láàrín.

19 Pilatu kọ ìwé kan pẹ̀, ó fi e lórí àgbélébùú náà. Ohun a kọ ni,

Jesu ti Nasareti Ọba àwọn Júù.

20 Nítorí náà, ̀pọ̀ àwọn Júù ni ó ka ìwé àkọlé yìí, nítorí ibi a gbé kan Jesu mọ́ àgbélébùú súnmọ́ etí ìlú, a kọ ́ èdè Heberu àti Latin, àti ti Giriki. 21 Nítorí náà àwọn olórí àlùfáà àwọn Júù fún Pilatu , "ṣe kọ, Ọba àwọn Júù,ṣùgbọ́n ọkùnrin yìí , èmi ni ọba àwọn Júù."

22 Pilatu dáhùn , ohun mo ti kọ, mo ti kọ ́.

23 Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ogun, nígbà wọ́n kan Jesu mọ́ àgbélébùú tán, wọ́n aṣọ rẹ̀, wọ́n pín wọn ipa mẹ́rin, apá kan fún ọmọ-ogun kọ̀̀kan, àti ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀ náà ojúràn-án, wọ́n hun ún láti òkè títí jálẹ̀.

24 19.24: Ek 28.32; Sm 22.18. Nítorí náà wọ́n fún ara wọn , "jẹ́ a á ya, ṣùgbọ́n a ṣẹ́ gègé nítorí rẹ̀."

Ti ẹni yóò jẹ́: ìwé mímọ́ ó le ṣẹ, ó ,

"Wọ́n pín aṣọ mi láàrín ara wọn,

wọ́n ṣẹ́ gègé fún aṣọ ìlekè mi."

Nǹkan wọ̀nyí ni àwọn ọmọ-ogun ṣe.

25 19.25: Mt 27.55-56; Mk 15.40-41; Lk 23.49; Jh 2.3; Mk 3.31; Lk 24.18; Jh 20.1,18. Ìyá Jesu àti arábìnrin ìyá rẹ̀ Maria aya Kilopa, àti Maria Magdalene dúró níbi àgbélébùú, 26 19.26: Jh 13.23; 20.2; 21.20.nígbà Jesu ìyá rẹ̀ àti ọmọ-ẹ̀yìn náà dúró, ẹni Jesu fẹ́ràn, ó fún ìyá rẹ̀ , "Obìnrin, wo ọmọ rẹ!" 27 Lẹ́yìn náà ni ó fún ọmọ-ẹ̀yìn náà , "Wo ìyá rẹ!" Láti wákàtí náà lọ ni ọmọ-ẹ̀yìn náà ti un lọ ilé ara rẹ̀.

Ikú Jesu

28 19.28-30: Sm 69.21; Mt 27.45-50; Mk 15.33-37; Lk 23.44-46; Jh 17.4. Lẹ́yìn èyí, Jesu ti mọ̀ , a ti parí ohun gbogbo tán, ìwé mímọ́ á ṣẹ, ó , "Òrùngbẹ ń gbẹ ." 29 Ohun èlò kan ó kún fún ọtí kíkan níbẹ̀, wọ́n tẹ kànìnkànìn ó kún fún ọtí kíkan bọ inú rẹ̀, wọ́n fi orí igi hísópù, wọ́n án i lẹ́nu. 30 Nígbà Jesu ti gba ọtí kíkan náà, ó , "Ó parí!" Ó tẹ orí rẹ̀ ba, ó jọ̀wọ́ ̀rẹ̀.

31 19.31: De 21.23; Ek 12.16. Nítorí ó jẹ́ ọjọ́ ìpalẹ̀mọ́, òkú wọn ba à lórí àgbélébùú ọjọ́ ìsinmi (nítorí ọjọ́ ńlá ni ọjọ́ ìsinmi náà), nítorí náà, àwọn Júù bẹ Pilatu a ṣẹ́ egungun itan wọn, a gbé wọn kúrò. 32 Nítorí náà, àwọn ọmọ-ogun , wọ́n ṣẹ́ egungun itan ti èkínní, àti ti èkejì, a kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀rẹ̀. 33 Ṣùgbọ́n nígbà wọ́n ̀dọ̀ Jesu, wọ́n i ó ti , wọn ṣẹ́ egungun itan rẹ̀, 34 19.34: 1Jh 5.6-8.ṣùgbọ́n ̀kan nínú àwọn ọmọ-ogun náà fi ̀kọ̀ gún un lẹ́gbẹ̀́, lójúkan náà, ̀jẹ̀ àti omi jáde. 35 19.35: Jh 15.27; 21.24.Ẹni ó jẹ́rìí, òtítọ́ ni ̀rẹ̀, ó mọ̀ òtítọ́ ni òun sọ, ̀yin ba à gbàgbọ́. 36 19.36: Ek 12.46; Nu 9.12; Sm 34.20.Nǹkan wọ̀nyí ṣe, ìwé mímọ́ ba à ṣẹ, ó , "A yóò fọ́ egungun rẹ̀." 37 19.37: Sk 12.10.Ìwé mímọ́ mìíràn pẹ̀, "Wọn ó máa wo ẹni a gún lọ́kọ̀."

Ìsìnkú Jesu

38 19.38-42: Mt 27.57-61; Mk 15.42-47; Lk 23.50-56. Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí Josẹfu ará Arimatea, ẹni ó jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn Jesu, ìkọ̀kọ̀, nítorí ìbẹ̀àwọn Júù, o bẹ Pilatu òun gbé òkú Jesu kúrò, Pilatu fún un àṣẹ. Nígbà náà ni ó , ó gbé òkú Jesu lọ. 39 19.39: Jh 3.1; 7.50.Nikodemu pẹ̀, ẹni ó tọ Jesu lóru lákọ̀́kọ́, ó àdàpọ̀ òjìá àti aloe , ó ìwọ̀n ọgọ́rùn-ún lita. 40 19.40: Mk 16.1; 14.8.Bẹ́̀ ni wọ́n gbé òkú Jesu, wọ́n fi aṣọ ̀gbọ̀ í pẹ̀tùràrí, gẹ́gẹ́ ìṣe àwọn Júù ti ìsìnkú wọn. 41 Àgbàlá kan níbi a gbé kàn án mọ́ àgbélébùú; ibojì tuntun kan nínú àgbàlá náà, nínú èyí a ì tẹ́ ẹnìkan . 42 Ǹjẹ́ níbẹ̀ ni wọ́n tẹ́ Jesu , nítorí ìpalẹ̀mọ́ àwọn Júù; àti nítorí ibojì náà nítòsí.

Veja também