Publicidade

João 21

Jesu àti iṣẹ́ ìyanu ẹja pípa

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, Jesu tún fi ara rẹ̀ hàn fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ létí Òkun Tiberia; báyìí ni ó farahàn. 2 21.2: Jh 11.16; 1.45; Lk 5.10.Simoni Peteru, àti Tomasi a ń Didimu, àti Natanaeli ará Kana ti Galili, àti àwọn ọmọ Sebede, àti àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ méjì mìíràn jùmọ̀ pọ̀. 3 21.3-6: Lk 5.3-7.Simoni Peteru fún wọn , "Èmi ń lọ pẹja!" Wọ́n fún un , "Àwa pẹ̀ń lọ." Wọ́n jáde, wọ́n wọ inú ọkọ̀ ojú omi; òru náà wọn ohunkóhun.

4 21.4: Jh 20.14; Lk 24.16. Ṣùgbọ́n nígbà ilẹ̀ bẹ̀rẹ̀ mọ́, Jesu dúró létí Òkun, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mọ̀ Jesu ni.

5 21.5: Lk 24.41. Jesu fún wọn , "̀yin ọmọdé, ẹja díẹ̀ ?"

Wọ́n a lóhùn , "Rárá o."

6 Ó fún wọn , "sọ àwọ̀n apá ̀tún ọkọ̀ ojú omi, ̀yin yóò ." Nígbà wọ́n ṣe bẹ́̀, wọn á jáde nítorí ̀pọ̀ ẹja.

7 21.7: Jh 13.23; 19.26; 20.2; 21.20. Nígbà náà ni ọmọ-ẹ̀yìn náà Jesu fẹ́ràn fún Peteru , "Olúwa ni!" Nígbà Simoni Peteru gbọ́ Olúwa ni, bẹ́̀ ni ó di àmùrè ̀rẹ̀ mọ́ra, nítorí ó ìhòhò, ó gbé ara rẹ̀ sọ sínú Òkun. 8 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ìyókù ọkọ̀ ojú omi kékeré kan nítorí wọn jìnà sílẹ̀, ṣùgbọ́n ìwọ̀n igba ìgbọ̀nwọ́; wọ́n ń wọ́ àwọ̀n náà ó kún fún ẹja. 9 Nígbà wọ́n gúnlẹ̀, wọ́n ̀yín iná níbẹ̀ àti ẹja lórí rẹ̀ àti àkàrà.

10 Jesu fún wọn , "nínú ẹja pa nísinsin yìí ." 11 Nítorí náà, Simoni Peteru gòkè, ó fa àwọ̀n náà wálẹ̀, ó kún fún ẹja ńlá, ó jẹ́ mẹ́tàléláàádọ́jọ (153) wọ́n ti pọ̀ náà, àwọ̀n náà ya. 12 Jesu fún wọn , "jẹun òwúrọ̀." ẹnìkan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ó jẹ́ i , "Ta ni ìwọ ṣe?" Nítorí wọ́n mọ̀ Olúwa ni. 13 Jesu , ó àkàrà, ó fi fún wọn, bẹ́̀ ni ẹja. 14 21.14: Jh 20.19,26.Èyí ni ìgbà kẹta nísinsin yìí Jesu farahan àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ lẹ́yìn ìgbà ó jíǹde kúrò nínú òkú.

Jesu fún Peteru iṣẹ́

15 21.15: Jh 1.42; 13.37; Mk 14.29-31; Lk 12.32. Ǹjẹ́ lẹ́yìn ìgbà wọ́n jẹun òwúrọ̀ tan, Jesu fún Simoni Peteru , "Simoni, ọmọ Jona, ìwọ fẹ́ mi ju àwọn wọ̀nyí lọ ?"

Ó fún un , "Bẹ́̀ ni Olúwa; ìwọ mọ̀ , mo fẹ́ràn rẹ."

Ó fún un , "Máa bọ́ àwọn àgùntàn mi."

16 21.16: Mt 2.6; Ap 20.28; 1Pt 5.2; If 7.17. Ó tún fún un nígbà kejì , "Simoni ọmọ Jona, ìwọ fẹ́ mi ?"

Ó fún un , "Bẹ́̀ ni Olúwa; ìwọ mọ̀ , mo fẹ́ràn rẹ."

Ó fún un , "Máa bọ́ àwọn àgùntàn mi."

17 Ó fún un nígbà kẹta , "Simoni, ọmọ Jona, ìwọ fẹ́ràn mi nítòótọ́ ?"

Inú Peteru bàjẹ́, nítorí ó fún un nígbà ̀kẹta , "Ìwọ fẹ́ràn mi nítòótọ́ ?" Ó fún un , "Olúwa, ìwọ mọ ohun gbogbo; ìwọ mọ̀ , mo fẹ́ràn rẹ."

Jesu fún un , "Máa bọ́ àwọn àgùntàn mi. 18 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo fún , nígbà ìwọ ̀dọ́mọdé, ìwọ a máa di ara rẹ àmùrè, ìwọ a máa rìn lọ ibi ìwọ fẹ́, ṣùgbọ́n nígbà ìwọ di arúgbó, ìwọ yóò na ọwọ́ rẹ jáde, ẹlòmíràn yóò ́ àmùrè, yóò lọ ibi ìwọ fẹ́." 19 21.19: 2Pt 1.14; Mk 1.17.Jesu èyí, ó fi ń ṣe àpẹẹrẹ irú ikú yóò fi yin Ọlọ́run lógo. Lẹ́yìn ìgbà ó ti èyí tan, ó fún un , "Máa tọ̀ lẹ́yìn."

20 21.20: Jh 13.25. Peteru yípadà, ó ọmọ-ẹ̀yìn náà, ẹni Jesu fẹ́ràn, ń bọ̀ lẹ́yìn; ẹni ó gbara le súnmọ́ àyà rẹ̀ nígbà oúnjẹ alẹ́ ó fún un , "Olúwa, ta ni ẹni yóò fi ́ hàn?" 21 Nígbà Peteru i, ó fún Jesu , "Olúwa, Eléyìí ha ń kọ́?"

22 21.22: 1Kọ 4.5; Jk 5.7; If 2.25; Mt 16.28. Jesu fún un , "èmi fẹ́ ó dúró títí èmi ó fi , kín ni èyí jẹ́ ? Ìwọ máa tọ̀ lẹ́yìn." 23 ̀rọ̀ yìí tàn láàrín àwọn arákùnrin , ọmọ-ẹ̀yìn náà yóò , ṣùgbọ́n Jesu fún un , òun yóò ; ṣùgbọ́n, "èmi fẹ́ ó dúró títí èmi ó fi , kín ni èyí jẹ́ ?"

24 21.24: Jh 15.27; 19.35. Èyí ni ọmọ-ẹ̀yìn náà, ó jẹ́rìí nǹkan wọ̀nyí, ó kọ̀nǹkan wọ̀nyí, àwa mọ̀ , òtítọ́ ni ̀rẹ̀.

25 21.25: Jh 20.30. ̀pọ̀lọpọ̀ ohun mìíràn pẹ̀ni Jesu ṣe, èyí a kọ̀wọn ̀kọ̀̀kan, mo gbogbo ayé pàápàá gba ìwé náà a kọ ́.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-04_21-26-40-