Publicidade

João 4

Jesu sọ̀rọ̀ pẹ̀obìnrin ara Samaria

1 Àwọn Farisi gbọ́ , Jesu ni, ó ń ṣe ìtẹ̀bọmi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn púpọ̀ ju Johanu lọ. 2 ó tilẹ̀ jẹ́ Jesu tìkára rẹ̀ ṣe ìtẹ̀bọmi ṣe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, 3 Ó fi Judea sílẹ̀, ó tún lọ Galili.

4 Òun láti kọjá láàrín Samaria. 5 Nígbà náà ni ó ìlú Samaria kan, a ń Sikari, ó súnmọ́ etí ilẹ̀ oko Jakọbu ti fi fún Josẹfu, ọmọ rẹ̀. 6 Kànga Jakọbu níbẹ̀. Nítorí ó rẹ Jesu nítorí ìrìn rẹ̀, bẹ́̀ ni ó jókòó létí kànga, ó jẹ́ ìwọ̀n wákàtí kẹfà ọjọ́.

7 Obìnrin kan, ará Samaria láti omi, Jesu fún un ṣe ìwọ yóò fún mi ni omi mu. 8 Nítorí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ti lọ ìlú láti lọ ra oúnjẹ.

9 Obìnrin ará Samaria náà sọ fún un , "Júù ni ìwọ, obìnrin ará Samaria ni èmi. Èétirí ìwọ ń béèrè ohun mímu lọ́wọ́ mi?" (Nítorí àwọn Júù í àwọn ará Samaria ṣe pọ̀.)

10 Jesu dáhùn, ó fún un , "Ìbá ṣe ìwọ mọ ̀bùn Ọlọ́run, àti ẹni ó fún , Fún mi ni omi mu, ìwọ ìbá ti béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, òun ìbá ti fi omi ìyè fún ."

11 Obìnrin náà fún un , "Alàgbà, ìwọ igbá-ìfami ìwọ ó fi omi, bẹ́̀ ni kànga náà , Níbo ni ìwọ ó ti omi ìyè náà? 12 Ìwọ pọ̀ ju Jakọbu baba wa lọ , ẹni ó fún wa kànga náà, òun tìkára rẹ̀ si mu nínú rẹ̀, àti àwọn ọmọ rẹ̀, àti àwọn ẹran ̀sìn rẹ̀?"

13 Jesu dáhùn, ó fún un , "Ẹnikẹ́ni ó mu nínú omi yìí, òǹgbẹ yóò tún gbẹ ́. 14 Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó mu nínú omi èmi ó fi fún un, òǹgbẹ yóò gbẹ ́ mọ́ láé; ṣùgbọ́n omi èmi ó fi fún un yóò di kànga omi nínú rẹ̀, yóò máa sun si ìyè àìnípẹ̀kun."

15 Obìnrin náà fún u , "Alàgbà, fún mi omi yìí, òǹgbẹ ó ṣe gbẹ , èmi ó fa omi níbí mọ́."

16 Jesu fún un , "Lọ pe ọkọ rẹ, ó padà ìhín yìí."

17 Obìnrin náà dáhùn, ó fún un , "Èmi ọkọ."

Jesu fún un , "Ìwọ́ dáhùn dáradára , èmi ọkọ: 18 Nítorí ìwọ ti ọkọ márùn-ún , ọkùnrin ìwọ báyìí í ṣe ọkọ rẹ. Ohun ó ṣẹ̀ṣẹ̀ sọ tán yìí, òtítọ́ ni."

19 Obìnrin náà fún un , "Alàgbà, mo wòye , wòlíì ni ìwọ ń ṣe. 20 Àwọn baba wa sìn lórí òkè yìí; ̀yin , Jerusalẹmu ni ibi ó yẹ à ti máa sìn."

21 Jesu fún un , "Gbà gbọ́ obìnrin yìí, àkókò náà ń bọ̀, nígbà yóò ṣe lórí òkè yìí tàbí Jerusalẹmu ni ̀yin ó máa sin Baba. 22 ̀yin ń sin ohun ̀yin mọ̀, àwa ń sin ohun àwa mọ̀, nítorí ìgbàlà ti ̀dọ̀ àwọn Júù . 23 Ṣùgbọ́n àkókò ń bọ̀, ó tán nísinsin yìí, nígbà àwọn olùsìn tòótọ́ yóò máa sin Baba ̀àti òtítọ́, nítorí irú wọn ni Baba ń ó máa sin òun. 24 ̀ni Ọlọ́run: àwọn ẹni ń sìn ín ṣe aláìsìn ín ̀àti òtítọ́."

25 Obìnrin náà fún un , mo mọ̀ , "Messia ń bọ̀ , a ń Kristi, nígbà Òun , yóò sọ ohun gbogbo fún wa."

26 Jesu sọ ́ di mọ̀ fún un , "Èmi ẹni ń sọ̀rọ̀ yìí ni Òun."

Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn pẹ̀Jesu

27 Lákokò ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , ẹnu wọ́n ó ń obìnrin sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n ẹnìkan ó , "ni ìwọ ń ?" tàbí "Èéṣe ìwọ fi ń a sọ̀rọ̀?"

28 Nígbà náà ni obìnrin náà fi ládugbó rẹ̀ sílẹ̀, ó ̀rẹ̀ pọ̀n lọ ìlú, ó fún àwọn ènìyàn , 29 "ọkùnrin kan, ẹni ó sọ ohun gbogbo mo ti ṣe fún mi, èyí ha jẹ́ Kristi náà?" 30 Nígbà náà ni wọ́n ti ìlú jáde, wọ́n tọ̀ ́ .

31 Láàrín èyí, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń rọ̀ ́ , "Rabbi, jẹun."

32 Ṣùgbọ́n ó fún wọn , "Èmi oúnjẹ láti jẹ, ̀yin mọ̀."

33 Nítorí náà ni àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń bi ara wọn lérè , "Ẹnìkan oúnjẹ fún un láti jẹ ?"

34 Jesu fún wọn , "Oúnjẹ mi ni láti ṣe ìfẹ́ ẹni ó rán mi, àti láti parí iṣẹ́ rẹ̀. 35 ̀yin ha , Ó ku oṣù mẹ́rin, ìkórè yóò ?ó, mo fún un yín, ṣí ojú yín sókè, wo oko; nítorí wọn ti pọ́n fún ìkórè. 36 Kódà báyìí, ẹni ó ń kórè ń gba owó ̀rẹ̀, ó si ń èso jọ ìyè àìnípẹ̀kun, ẹni ó ń fúnrúgbìn àti ẹni ń kórè jọ máa yọ̀ pọ̀. 37 Nítorí nínú èyí ni ̀rọ̀ náà fi jẹ́ òtítọ́, Ẹnìkan ni ó fúnrúgbìn, ẹlòmíràn ni ó ń kórè jọ. 38 Mo rán yín lọ kórè ohun ṣiṣẹ́ fún. Àwọn ẹlòmíràn ti ṣiṣẹ́, ̀yin kórè èrè làálàá wọn."

̀pọ̀ ara Samaria gbàgbọ́

39 ̀pọ̀ àwọn ará Samaria láti ìlú náà gbà á gbọ́ nítorí ìjẹ́rìí obìnrin náà , "Ó sọ gbogbo ohun mo ti ṣe fún mi." 40 Nítorí náà, nígbà àwọn ará Samaria sọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n rọ̀ ́ , ó pẹ̀wọn, ó dúró fún ọjọ́ méjì. 41 Àwọn ̀pọ̀lọpọ̀ gbàgbọ́ i nítorí ̀rọ̀ rẹ̀.

42 Wọ́n fún obìnrin náà , "í ṣe nítorí ̀rọ̀ rẹ nìkan ni àwa ṣe gbàgbọ́, nítorí àwa tìkára wa ti gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀, àwa mọ̀ , nítòótọ́ èyí ni Kristi náà, Olùgbàlà aráyé."

Jesu wo ọmọkùnrin ọlọ́san

43 Lẹ́yìn ọjọ́ méjì ó ti ibẹ̀ kúrò, ó lọ Galili. 44 Nítorí Jesu tìkára rẹ̀ ti jẹ́rìí , Wòlíì í ọlá ilẹ̀ òun tìkára rẹ̀. 45 Nítorí náà nígbà ó Galili, àwọn ará Galili gbà á, nítorí ti wọ́n ti ohun gbogbo ó ṣe Jerusalẹmu nígbà àjọ ìrékọjá; nítorí àwọn tìkára wọn lọ àjọ pẹ̀.

46 Bẹ́̀ ni Jesu tún Kana ti Galili, níbi ó gbé sọ omi di wáìnì. Ọkùnrin ọlọ́kan , ẹni ara ọmọ rẹ̀ Kapernaumu. 47 Nígbà ó gbọ́ Jesu ti Judea Galili, ó tọ̀ ́ , ó ń bẹ̀ ́, ó sọ̀kalẹ̀ ó ọmọ òun láradá: nítorí ó ojú ikú.

48 Nígbà náà ni Jesu fún un , "ṣe ̀yin àmì àti iṣẹ́ ìyanu, ̀yin yóò gbàgbọ́ láé."

49 Ọkùnrin ọlọ́náà fún un , "Olúwa, sọ̀kalẹ̀ ọmọ mi ."

50 Jesu fún un , "Máa ̀rẹ lọ; ọmọ rẹ yóò ."

Ọkùnrin náà gba ̀rọ̀ Jesu gbọ́, ó kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀. 51 ó ti ń sọ̀kalẹ̀ lọ, àwọn ọmọ ̀dọ̀ rẹ̀ pàdé rẹ̀, wọ́n fún un , ọmọ rẹ ti . 52 Nígbà náà ni ó béèrè wákàtí ara rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ í lọ́wọ́ wọn, wọ́n fún un , "àná, wákàtí keje ni ibà náà fi í sílẹ̀."

53 Bẹ́̀ ni baba náà mọ̀ wákàtí kan náà ni, nínú èyí Jesu fún un "Ọmọ rẹ̀ ." Òun tìkára rẹ̀ gbàgbọ́, àti gbogbo ilé rẹ̀.

54 Èyí ni iṣẹ́ àmì kejì Jesu ṣe nígbà ó ti Judea jáde Galili.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-