Publicidade

João 5

21 Nítorí , gẹ́gẹ́ Baba ti ń òkú dìde, ó ń sọ wọ́n di alààyè: bẹ́̀ ni ọmọ ń sọ àwọn ó fẹ́ di alààyè pẹ̀. 22 Nítorí Baba í ṣe ìdájọ́ ẹnikẹ́ni, ṣùgbọ́n ó ti fi gbogbo ìdájọ́ ọmọ lọ́wọ́, 23 gbogbo ènìyàn máa fi ọlá fún ọmọ gẹ́gẹ́ wọ́n ti ń fi ọlá fún Baba. Ẹnikẹ́ni fi ọlá fún ọmọ, fi ọlá fún Baba ó ran an.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-