Publicidade

João 5

Ìwòsàn etí odò adágún

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, àjọ àwọn Júù kan ; Jesu gòkè lọ Jerusalẹmu. 2 Adágún omi kan Jerusalẹmu, létí bodè àgùntàn, a ń Betisaida èdè Heberu, ó ẹnu-ọ̀márùn-ún. 3 ̀gbẹ́ odò yìí ni ̀pọ̀ àwọn abirùn ènìyàn máa ń gbé dùbúlẹ̀ , àwọn afọ́, arọ àti aláàrùn ̀gbà. 5 Ọkùnrin kan níbẹ̀, ẹni ó àìlera fún ọdún méjìdínlógójì. 6 Jesu ti i ìdùbúlẹ̀, ó mọ̀ ó pẹ́ ó ti bẹ́̀, ó fún un , "Ìwọ fẹ́ a láradá ?"

7 Abirùn náà a lóhùn , "Arákùnrin, èmi ẹni ìbá gbé mi sínú adágún, nígbà a ń omi náà, èmi ti ń bọ̀ , ẹlòmíràn a sọ̀kalẹ̀ sínú rẹ̀ síwájú mi."

8 Jesu fún un , "Dìde, gbé àkéte rẹ, o máa rìn." 9 Lọ́gán, a ọkùnrin náà láradá, ó gbé àkéte rẹ̀, ó ń rìn.

Ọjọ́ náà jẹ́ ọjọ́ ìsinmi. 10 Nítorí náà àwọn Júù fún ọkùnrin náà a láradá , "Ọjọ́ ìsinmi ni òní; tọ́ fún láti gbé àkéte rẹ."

11 Ó wọn lóhùn , "Ẹni ó mi láradá, ni ó fún mi , Gbé àkéte rẹ, o máa rìn.’ "

12 Nígbà náà ni wọ́n bi í lérè , "Ọkùnrin wo ni ẹni ó fún gbé àkéte rẹ, o máa rìn?"

13 Ẹni a láradá náà mọ̀ ẹni ó jẹ́ nítorí Jesu ti kúrò níbẹ̀, àwọn ènìyàn púpọ̀ níbẹ̀.

14 Lẹ́yìn náà, Jesu i nínú tẹmpili ó fún un , "ó, a láradá: ṣe dẹ́ṣẹ̀ mọ́, ohun ó burú ju èyí lọ ba à !" 15 Ọkùnrin náà lọ, ó sọ fún àwọn Júù , Jesu ni ẹni ó òun láradá.

Àṣẹ Ọmọ Ọlọ́run

16 Nítorí èyí ni àwọn Júù ṣe inúnibíni Jesu, wọ́n ń ̀láti pa á, nítorí o ń ṣe nǹkan wọ̀nyí ọjọ́ ìsinmi. 17 Ṣùgbọ́n Jesu wọn lóhùn , "Baba mi ń ṣiṣẹ́ títí di ìsinsin yìí, èmi náà ń ṣiṣẹ́." 18 Nítorí èyí ni àwọn Júù túbọ̀ ń ̀láti pa á, í ṣe nítorí ó ba ọjọ́ ìsinmi jẹ́ nìkan ni, ṣùgbọ́n ó pẹ̀, Baba òun ni Ọlọ́run jẹ́, ó ń ara rẹ̀ Ọlọ́run dọ́gba.

19 Nígbà náà ni Jesu dáhùn, ó fún wọn , "Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo fún yín, ọmọ ṣe ohunkóhun fún ara rẹ̀, ṣe ohun ó Baba ń ṣe, nítorí ohunkóhun baba ń ṣe, ìwọ̀nyí ni ọmọ náà ń ṣe pẹ̀. 20 Nítorí Baba fẹ́ràn ọmọ, ó ti fi ohun gbogbo ó ń ṣe hàn án, òun yóò fi iṣẹ́ ó tóbi wọ̀nyí lọ hàn án, ẹnu yín. 21 Nítorí , gẹ́gẹ́ Baba ti ń òkú dìde, ó ń sọ wọ́n di alààyè: bẹ́̀ ni ọmọ ń sọ àwọn ó fẹ́ di alààyè pẹ̀. 22 Nítorí Baba í ṣe ìdájọ́ ẹnikẹ́ni, ṣùgbọ́n ó ti fi gbogbo ìdájọ́ ọmọ lọ́wọ́, 23 gbogbo ènìyàn máa fi ọlá fún ọmọ gẹ́gẹ́ wọ́n ti ń fi ọlá fún Baba. Ẹnikẹ́ni fi ọlá fún ọmọ, fi ọlá fún Baba ó ran an.

24 "Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo fún yín, ẹnikẹ́ni ó gbọ́ ̀rọ̀ mi, ó gba ẹni ó rán mi gbọ́, ó ìyè nípẹ̀kun, òun yóò ìdájọ́; ṣùgbọ́n ó ti ikú kọjá bọ́ ìyè. 25 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo fún yín, wákàtí náà ń bọ̀, ó tán nísinsin yìí, nígbà àwọn òkú yóò gbọ́ ohùn Ọmọ Ọlọ́run, àwọn ó gbọ́ yóò . 26 Nítorí gẹ́gẹ́ Baba ti ìyè nínú ara rẹ̀; gẹ́gẹ́ bẹ́̀ ni ó fi fún ọmọ láti ìyè nínú ara rẹ̀; 27 Ó fún un àṣẹ láti máa ṣe ìdájọ́ pẹ̀, nítorí òun jẹ́ Ọmọ Ènìyàn.

28 "èyí ṣe yín lẹ́nu; nítorí wákàtí ń bọ̀, nínú èyí gbogbo àwọn ó ibojì yóò gbọ́ ohun rẹ̀. 29 Wọn ó jáde ; àwọn ó ṣe rere, àjíǹde ìyè; àwọn ó ṣe búburú àjíǹde ìdájọ́. 30 Èmi le ṣe ohun kan fún ara mi, mo ti ń gbọ́ ni, mo ń dájọ́, òdodo ni ìdájọ́ mi; nítorí èmi ìfẹ́ ti èmi fúnra mi, ṣe ìfẹ́ ti ẹni ó rán mi.

Àwọn ̀nípa Jesu

31 "èmi ń jẹ́rìí ara mi, ̀mi í ṣe òtítọ́. 32 Ẹlòmíràn ni ẹni ń jẹ́rìí mi; èmi mọ̀ , òtítọ́ ni ̀mi ó jẹ́.

33 "̀yin ti ránṣẹ́ lọ sọ́dọ̀ Johanu, òun ti jẹ́rìí òtítọ́. 34 Ṣùgbọ́n èmi gba ̀lọ́dọ̀ ènìyàn, nǹkan wọ̀nyí ni èmi ń sọ, ̀yin . 35 Òun ni fìtílà ó ń , ó ń tànmọ́lẹ̀, ̀yin fẹ́ fún à kan láti máa yọ̀ nínú ìmọ́lẹ̀ rẹ̀.

36 "Ṣùgbọ́n èmi ̀ó pọ̀ti Johanu lọ. Nítorí iṣẹ́ Baba ti fi fún mi láti ṣe parí, iṣẹ́ náà pàápàá èmi ń ṣe náà ń jẹ́rìí mi , Baba ni ó rán mi. 37 Àti Baba tìkára rẹ̀ ó rán mi ti jẹ́rìí mi. ̀yin gbọ́ ohùn rẹ̀ nígbà kan , bẹ́̀ ni ìrísí rẹ̀. 38 ̀rọ̀ rẹ̀ láti máa gbé inú yín, nítorí ẹni ó rán, òun ni ̀yin gbàgbọ́. 39 ̀yin ń ìwé mímọ́ nítorí ̀yin nínú wọn ni ̀yin ìyè nípẹ̀kun. Wọ̀nyí ni àwọn ó ń jẹ́rìí mi. 40 ̀yin fẹ́ láti sọ́dọ̀ mi, ̀yin ba à ìyè.

41 "Èmi gba ògo lọ́dọ̀ ènìyàn. 42 Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ , ̀yin fúnra yín ìfẹ́ Ọlọ́run nínú yín. 43 Èmi orúkọ Baba mi, ̀yin gbà ; ẹlòmíràn orúkọ ara rẹ̀, òun ni ̀yin yóò gbà. 44 ̀yin ó ti ṣe gbàgbọ́, ̀yin ń gba ògo lọ́dọ̀ ara yín ògo ó ti ̀dọ̀ Ọlọ́run nìkan ?

45 "ṣe , èmi ó fi yín sùn lọ́dọ̀ Baba, ẹni ń fi yín sùn , àní Mose, ẹni ̀yin gbẹ́kẹ̀. 46 Nítorí ̀yin ìbá gba Mose gbọ́, ̀yin ìbá gbà gbọ́, nítorí ó kọ ìwé nípa tèmi. 47 Ṣùgbọ́n ̀yin gba ìwé rẹ̀ gbọ́, ̀yin ó ti ṣe gbà ̀rọ̀ mi gbọ́?"

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-